< 1 Corinthians 5 >
1 Ìròyìn rẹ ń tàn kalẹ̀ pé ìwà àgbèrè wa láàrín yín, irú àgbèrè tí a kò tilẹ̀ gbúròó rẹ̀ láàrín àwọn aláìkọlà pé, ẹnìkan nínú yín ń fẹ́ ìyàwó baba rẹ̀.
Nami ksunga hüipawmnak kyühkse akcanga veki tia ngthang hüki; acun hin khyang kcee üng pi am ve. Ami paa khyu kdik ihpüikie ti cun na mthehkie.
2 Ẹ̀yin ń ṣe ìgbéraga! Ẹ̀yin kò kúkú káàánú kí a lè mú ẹni tí ó hu ìwà yìí kúrò láàrín yín?
Ihawkba nami awhcah khai ni. Acukba veki cun thüiseinak vai ni. Nami vei üngkhyüh pi ksät vai sü.
3 Lóòtítọ́ èmi kò sí láàrín yín nípa ti ara, ṣùgbọ́n mo wà lọ́dọ̀ yín nínú ẹ̀mí àti pé, ní orúkọ Olúwa Jesu Kristi, mo tí ṣe ìdájọ́ lórí irú ẹni bẹ́ẹ̀, bí ẹni pé mo wá láàrín yín.
Ka pumsa am thuk lüpi Ngmüimkhya am nami hlawnga ka veki. Aksekhyua vekia khana Bawi Jesuh naw ngthumkhyah khaia kei naw pyen veng. Nangmi atänga nami nghmuh akba kei naw Ngmüimkhya am ka ning jah hmuh ngüse ni Bawi Jesuha johit naw atänga jah vepüiki.
4 Ní orúkọ Jesu Kristi. Nígbà tí ẹ̀yin bá péjọ, àti ẹ̀mí mi si wa pẹ̀lú yin nínú ẹ̀mí mi àti pẹ̀lú agbára Jesu Kristi Olúwa wa.
5 Kí ẹ fi irú ẹni bẹ́ẹ̀ lé Satani lọ́wọ́ fún ìparun ara, kí ó ba à le gba ẹ̀mí rẹ là ní ọjọ́ Olúwa wa Jesu Kristi.
Khyang acuna mäih cun a Ngmüimkhya Bawipa khaw mhnüp üng küikyannak a yah vaia, a pumsa khyükleih khaia Khawyama veia ap ua.
6 Ìṣeféfé yín kò dára. Ẹ̀yin kò mọ̀ pé ìwúkàrà díẹ̀ ní mú gbogbo ìyẹ̀fun di wíwú?
Nami awhcah hin am daw ve. Nghngen apica naw bu angkhä thawh saki ti am nami ksingki aw?
7 Nítorí náà ẹ mú ìwúkàrà àtijọ́ kúrò nínú yín, kí ẹ̀yin kí ó lè jẹ ìyẹ̀fun tuntun, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin tí jẹ àkàrà ti kò ní ìwúkàrà. Nítorí à ti fi ìrékọjá wa, àní Kristi ni a ti pa láti fi ṣe ẹbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ wa.
Mkhyenaka nghngen kphyüm cän loin ua, acukba ani üngva avana nami caih khai. Tuhta nghngen am ngcawki buh tawh üng nami täng khai. Nangmi cun akcanga nami ngcimki he ni. Mi lätnak pawi pi ngsäm hnüh ve, mi lätnak pawhnak vai Khritaw pi hnim päng ve u.
8 Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á pa àjọ náà mọ́, kì í ṣe pẹ̀lú ìwúkàrà àtijọ́ bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe pẹ̀lú ìwúkàrà àrankàn àti ìwà búburú, ṣùgbọ́n pẹ̀lú àkàrà tí kò ní ìwúkàrà, àkàrà òtítọ́ àti òdodo.
Acunakyase, mkhyekatnaka nghngnen akphyüm am kcawa muk am ni lü, nghngnen käh kcawa muk ngcimcaihnak ja ngthungtak am lätnak mi pawh vai u.
9 Nígbà tí mo kọ̀wé ṣáájú sí i yín, mo sọ fún yín pé, kí ẹ má ṣe darapọ̀ pẹ̀lú àwọn alágbèrè ènìyàn.
Ka cayuk üng hüipawmkie käh nami jah ngpawngpüi vaia ka ning ja mthehki.
10 Nígbà tí mo sọ bẹ́ẹ̀ ń kò sọ̀rọ̀ nípa àwọn tí ayé yìí, tí wọ́n ń gbé ìgbé ayé wọn nínú ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè, àti àwọn olójúkòkòrò tí ń rẹ́ ni jẹ, àwọn olè àti àwọn abọ̀rìṣà. Nítorí ó dájú pé ẹ̀yin gbọdọ̀ kúrò nínú ayé yìí láti yẹra fún wọn.
Ka tinak hlü ta hüipawmkie, mpyukei he, juktuh hjawkhahkie käh jah ngpawngpüi ka tinak am ni. Khawmdek üng käh nami sängei vaia jah hjawng kung ua.
11 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí mo kọ̀wé sí i yín pé, bí ẹnikẹ́ni tí a pe rẹ̀ ni arákùnrin bá jẹ́ àgbèrè, tàbí wọ̀bìà, tàbí abọ̀rìṣà, àti ẹlẹ́gàn, tàbí ọ̀mùtípara, tàbí alọ́nilọ́wọ́gbà. Kí ẹ tilẹ̀ bá irú ẹni bẹ́ẹ̀ jẹun.
Ka tinak hlü ta jumeikia ngsui lü hüipawmki, mpyuki, ngvawk pawhki, juktuh hjawkhahki, khyang hnimki, ju awki he cun atänga ngaw lü ei pi käh jah eipüi u.
12 Nítorí èwo ni tèmi láti máa ṣe ìdájọ́ àwọn tí ń bẹ lóde? Kì í ha ṣe àwọn tí ó wà nínú ni ẹ̀yin ṣe ìdájọ́ wọn?
Akcee ngthu jah mkhya pet vai cun keia bilawh vai am ni. Pamhnam naw jah mkhyah pe khai. Acunsepi namäta püie cun nami jah mkhya pe khai am ni aw? Cangcim naw a pyena kba “Am dawkia khyang nami ksung üngkhyüh jah ksät ua.”
13 Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ àwọn tí ó ń bẹ lóde. “Ẹ lé àwọn ènìyàn búburú náà kúrò láàrín yín.”