< 1 Chronicles 9 >

1 Gbogbo Israẹli ni a kọ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá nínú ìwé àwọn ọba Israẹli. Àwọn ènìyàn Juda ni a kó ní ìgbèkùn lọ sí Babeli nítorí àìṣòótọ́ wọn.
PELA o ka Iseraela a pau i heluia'i ma na hanauna: aia hoi, ua kakauia lakou iloko o ka buke a na alii o ka Iseraela a o ka Iuda, ka poe i laweia aku i Babulona no na lawehala o lakou.
2 Nísinsin yìí, àwọn tí ó kọ́kọ́ tún tẹ̀dó lórí ohun ìní wọn ní ìlú wọn ni díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa.
A o na kanaka mua i noho ma ko lakou mau wahi noho i na kulanakauhale o lakou, o lakou ka Iseraela, o na kahuna, a o na Levi, a me ka poe Netini.
3 Àwọn tí ó wá láti Juda láti Benjamini àti láti Efraimu àti Manase tí ó ń gbé ní Jerusalẹmu jẹ́:
A ma Ierusaiema i noho ai kekahi poe mamo a Iuda, a o kekahi poe mamo a Beniamina, a o kekahi poe mamo a Eperaima laua o Manase;
4 Uttai ọmọ Ammihudu, ọmọ Omri, ọmọ Imri, ọmọ Bani, ìran ọmọ Peresi ọmọ Juda.
O Utai ke keiki a Amihuda, ke keiki a Omeri, ke keiki a Imeri, ke keiki a Bani, no na mamo a Pareza ke keiki a Iuda.
5 Àti nínú ará Ṣilo: Asaiah àkọ́bí àti àwọn ọmọ rẹ̀.
A no ka poe Siloni; o Asaia ka hanau mua, a me kana mau keikikane.
6 Ní ti ará Sera: Jeueli. Àwọn ènìyàn láti Juda sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́wàá.
A no na mamo a Zera; o Ieuela, a o ko lakou poe hoahanau, eono haneri a me kanaiwa.
7 Àti nínú àwọn ọmọ Benjamini ni: Sallu ọmọ Meṣullamu, ọmọ Hodafiah; ọmọ Hasenuah;
A no na mamo a Beniamina; o Salu ke keiki a Mesulama, ke keiki a Hodavia, ke keiki a Hasenua.
8 Ibinaiah ọmọ Jerohamu; Ela ọmọ Ussi, ọmọ Mikri; àti Meṣullamu ọmọ Ṣefatia; ọmọ Reueli, ọmọ Ibinijah.
A o Ibeneia ke keiki a Ierohama, a o Ela ke keiki a Uzi, ke keiki a Mikeri, a o Mesulama ke keiki a Sepatia, ke keiki a Reuela, ke keiki a Ibeuiia.
9 Àwọn ènìyàn láti Benjamini gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ ọ́ nínú ìran wọn nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó dín mẹ́rìnlélógójì. Gbogbo àwọn ọkùnrin yí jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé.
A o ko lakou poe hoahanau, ma ko lakou mau hanauna, he eiwa haneri a me ke kanalimakumamaono. He poe lunaohana lakou nei a pau, ma ka ohana o ko lakou mau makuakane.
10 Ní ti àwọn àlùfáà: Jedaiah; Jehoiaribi; Jakini;
A no na kahuna; o Iedaia, o Iehoiariba, a o Iakina.
11 Asariah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, olórí tí ó ń bojútó ilé Ọlọ́run;
A o Azaria keiki a Hilekia, ke keiki a Mesulama, ke keiki a Zadoka, ke keiki a Meraiota, ke keiki a Ahituba, a ka luna no ka hale o ke Akua;
12 Adaiah ọmọ Jerohamu, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malkiah; àti Masai ọmọ Adieli, ọmọ Jahisera, ọmọ Meṣullamu ọmọ Meṣilemiti, ọmọ Immeri.
A o Adaia ke keiki a Ierohama, ke keiki a Pasura, ke keiki a Malekiia; a o Masia ke keiki a Adiela, ke keiki a Iahezera, ke keiki a Mesulama, ke keiki a Mesilemita, ke keiki a Imera;
13 Àwọn àlùfáà, tí wọ́n jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀sán ó dín méjì. Wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin, tí wọ́n lè dúró fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú ilé Ọlọ́run.
A o ke lakou poe hoahanau, na lunaohana o ko lakou mau makua, hookahi tausani me na haneri ehiku a me ke kanaono: he poe kanaka ikaika loa e hana i ka hana o ka hale o ke Akua.
14 Ní ti àwọn ará Lefi: Ṣemaiah ọmọ Haṣubu, ọmọ Asrikamu, ọmọ Haṣabiah ará Merari;
A no ka Levi: o Semaia ke keiki a Hasuba, ke keiki a Azerikama, ke keiki a Hasabia, no na mamo a Merari;
15 Bakibakari, Hereṣi, Galali àti Mattaniah, ọmọ Mika, ọmọ Sikri, ọmọ Asafu;
A o Bakebaka, o Heresa, o Galala, o Matania ke keiki a Mika, ke keiki a Zikeri, ke keiki a Asapa;
16 Obadiah ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni; àti Berekiah ọmọ Asa, ọmọ Elkana, tí ó ń gbé nínú àwọn ìlú àwọn ará Netofa.
A o Obadia ke keiki a Semaia, ke keiki a Galala, ke keiki a Iedu. tuna; a o Berekia ke keiki a Asa, ke keiki a Elekana, ka mea i noho ma na kulanahale o ka Netopata.
17 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà: Ṣallumu, Akkubu, Talmoni, Ahimani àti arákùnrin wọn, Ṣalumu olóyè wọn,
A o ka poe kiaipuka, o Saluma, o Akuba, o Talemona, o Ahimana, a me ko lakou poe hoahanau: a o Saluma ka luna:
18 ti wà ní ipò ìdúró ní ẹnu-ọ̀nà ọba ní apá ìhà ìlà-oòrùn títí di àkókò yí. Wọ̀nyí ni àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà tí ó jẹ́ ti ìpàgọ́ àwọn ará Lefi.
Mamua, noho lakou ma ka ipuka o ke alii, ma ka aoao hikina; he poe kiaipuka lakou iwaena o na poe mamo a Levi.
19 Ṣallumu ọmọ Kore ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora, àti àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀. Láti ìdílé rẹ̀ (àwọn ará Korati) ni ó dúró fún ṣíṣọ́ ìloro ẹnu-ọ̀nà àgọ́ gẹ́gẹ́ bí baba wọn ti ń dúró fún ṣíṣọ́ àbáwọlé ibùgbé Olúwa.
A o Saluma ke keiki a Kore, ke keiki a Ebiasapa, ke keiki a Kora, a o kona poe hoahanau, no ka ohana o kona makuakane, ko Kora, maluna lakou o ka oihana hoomana, na kiaipuka hoi o ka halelewa: a o ko lakou poe makuakane maluna o ke anainakanaka o Iehova, he poe malama lakou i kahi komo.
20 Ní ìgbà àkọ́kọ́ Finehasi ọmọ Eleasari jẹ́ olórí fún àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà, Olúwa sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
A o Pinehasa ke keiki a Eleazara ka luna o lakou, i ka manawa mamua, a me ia pu no o Iehova.
21 Sekariah, ọmọ Meṣelemiah jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àbáwọlé sí àgọ́ ibi ìpàdé.
A o Zekaria ke keiki a Meselemia ke kiaipuka ma ka puka o ka halelewa anaina.
22 Gbogbo rẹ̀ lápapọ̀, àwọn tí a yàn láti jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àwọn ìloro jẹ́ igba ó lé méjìlá. A ka àwọn wọ̀nyí nípa ìdílé ní ìletò wọn. Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ni a ti yàn sí ipò láti ọ̀dọ̀ Dafidi àti Samuẹli, aríran, nítorí òtítọ́ wọn.
O keia poe a pau i waeia he poe kiaipuka, elua haneri a me ka umikumamalua. Ua heluia lakou ma ko lakou hanauna, iloko o ko lakou mau kulanahale; o ka poe a Davida laua o Samuela ke kaula i hoonoho ai ma ka lakou oihana.
23 Àwọn àti àwọn ọmọ wọn ni ó wà fún ṣíṣọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa ilé tí a pè ní àgọ́.
Pela no ia lakou a me na keiki a lakou ke kiai ana o na ipuka o ka hale o Iehova, o ka halelewa, ma na papa.
24 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà wà ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin: ìlà-oòrùn, ìwọ̀-oòrùn àríwá àti gúúsù.
Ma na aoao eha i noho ai na kiaipuka, ma ka hikina, ma ke komohana, ma ke kukuluakau, a ma ke kukuluhema.
25 Àwọn arákùnrin wọn ní àwọn ìletò wọn ní láti wá ní àkókò dé àkókò láti pín iṣẹ́ ìsìn wọn fún àkókò ọjọ́ méje.
A hala ae la na la ehiku, hele mai la na hoahanau o lakou, mai na kulanahale o lakou mai, i kela manawa i keia manawa me lakou.
26 Ṣùgbọ́n àwọn olórí alábojútó ẹnu-ọ̀nà mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí wọ́n jẹ́ ará Lefi ni a yàn fún àwọn iyàrá àti àwọn àpótí ìṣúra ní ilé Ọlọ́run.
No ka mea, o keia poe Levi, o na luna kiaipuka eha, i noho ma ka lakou oihana, a maluna o na hale ahuwaiwai a me na waihonakala o ka hale o ke Akua.
27 Wọ́n á lo gbogbo òru ní dídúró yí ilé Ọlọ́run ká, nítorí wọ́n ní láti ṣọ́ ọ, wọ́n sì ní àṣẹ sí kọ́kọ́rọ́ fún ṣíṣí i ní àràárọ̀.
A moe iho la lakou a puni i ka hale o ke Akua, no ka mea, maluna o lakou ke kiai ana, a ia lakou hoi ka wehe ana o ka hale ia kakahiaka ae ia kakahiaka ae.
28 Díẹ̀ wà ní ìdí ohun èlò tí à ń lò fún ìsìn ilé Ọlọ́run; wọn a máa kà á nígbà tí wọ́n gbé e wọlé àti nígbà tí a kó wọn jáde.
A i kekahi poe o lakou ka malama ana i na ipu mea lawelawe, i lawe mai ai lakou ia mau mea iloko, a e lawe aku hoi lakou ia mau mea iwaho, ma ka helu ana.
29 Àwọn mìíràn ni a yàn láti bojútó ohun èlò àti gbogbo ohun èlò ilé tí a yà sọ́tọ̀ fún Ọlọ́run, àti ìyẹ̀fun àti ọtí èso àjàrà àti òróró náà, tùràrí àti tùràrí olóòórùn dídùn.
Ua hoonohoia hoi kekahi poe o lakou e kiai i na ipu, a me na mea paahana a pau o ka luakini, i ka paiaoa, i ka waina, me ka aila, me ka libano, a me ka mea ala.
30 Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú àwọn àlùfáà ni ó ń bojútó pípò tùràrí olóòórùn dídùn papọ̀.
A na kekahi poe keiki a na kahuna i hana i ka mea poni ala.
31 Ará Lefi tí a sọ ní Mattitiah àkọ́bí ọmọkùnrin Ṣallumu ará Kora ni a yàn, tí ń ṣe alábojútó ohun tí a dín.
A o Matitia o ka Levi, o ka hiapo a Saluma ka Kora, ia ia ke kauoha maluna o na mea i hanaia maloko o na pa.
32 Àti nínú àwọn arákùnrin wọn, nínú àwọn ọmọ Kohati tó ń ṣe ìtọ́jú àkàrà ìfihàn, láti máa pèsè rẹ̀ ní ọjọọjọ́ ìsinmi.
A o kekahi poe hoahanau o lakou, o na keiki a ka Kohata, maluna lakou o ka berena hoike, e hoomakaukau ia mea no kela Sabati keia Sabati.
33 Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọkùnrin, olórí àwọn ìdílé Lefi dúró nínú àgọ́ ilé Olúwa, wọn kò sì ṣe lára iṣẹ́ ìsìn yòókù nítorí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ náà lọ́sàn, lóru.
O keia ka poe mele, na pookela o na makua o na Levi, i noho hana ole ma na keena: no ka mea, ua mau lakou ma ia hana i ka po a me ke ao.
34 Gbogbo wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn Lefi, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
O keia poe lunaohana o na Levi, he poe pookela ma ko lakou mau hanauna; a noho iho lakou ma Ierusalema.
35 Jeieli baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Orúkọ ìyàwó rẹ̀ a máa jẹ́ Maaka,
A ma Gibeona i noho ai ka makuakane o Gibeona, o Iehiela, O Maaka ka inoa o kana wahine.
36 pẹ̀lú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀ jẹ́ Abdoni, tí wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu.
O Abedona kana keiki hiapo, alaila o Zura, o Kisa, o Baala, o Nera, o Nadaba.
37 Gedori, Ahio, Sekariah àti Mikiloti.
O Gedora, o Ahio, o Zekaria a o Mikelota.
38 Mikiloti jẹ́ baba Ṣimeamu, àwọn náà ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
Na Mikelota, o Simeama; a noho iho la hoi lakou i Ierusalema me ko lakou poe hoahanau, i kahi ku pono aku i ko lakou poe hoahanau.
39 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba a Saulu, àti Saulu baba a Jonatani, àti Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
Na Nera o Kisa, na Kisa o Saula, na Saula o Ionatana, o Malikisua, o Abinadaba, a o Esebaala.
40 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali, tí ó jẹ́ baba Mika.
A o Meribaala ke keikikane a Ionatana: na Meribaala o Mika.
41 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni. Meleki, Tarea àti Ahasi.
O na keikikane a Mika, o Pitono, o Meleka, o Taherea, [a o Ahaza.]
42 Ahasi jẹ́ baba Jada, Jada jẹ́ baba Alemeti, Asmafeti, Simri, sì Simri jẹ́ baba Mosa.
Na Abaza o Iara, na Iara o Alemeta, o Azemaveta, o Zimeri; a na Zimeri o Moza.
43 Mosa jẹ́ baba Binea; Refaiah jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
Na Moza o Binea; a o Repaia kana keiki, o Eleasa kana keiki, a o Azela kana keiki.
44 Aseli ní ọmọ mẹ́fà, pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli Ṣeariah, Obadiah àti Hanani, gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Na Azela na keikikane eono; eia ko lakou mau inoa, o Azerikama, o Bokeru, o Isemaela, o Searia, o Obadia, a o Hanana: o lakou na keikikane a Azela.

< 1 Chronicles 9 >