< 1 Chronicles 9 >

1 Gbogbo Israẹli ni a kọ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá nínú ìwé àwọn ọba Israẹli. Àwọn ènìyàn Juda ni a kó ní ìgbèkùn lọ sí Babeli nítorí àìṣòótọ́ wọn.
Andũ a Isiraeli othe nĩmandĩkĩtwo maandĩko-inĩ ma njiarwa marĩa maarĩ mbuku-inĩ ya athamaki a Isiraeli. Andũ a Juda nĩmatahĩtwo magatwarwo Babuloni nĩ ũndũ wa kwaga kwĩhokeka.
2 Nísinsin yìí, àwọn tí ó kọ́kọ́ tún tẹ̀dó lórí ohun ìní wọn ní ìlú wọn ni díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa.
Na rĩrĩ, andũ arĩa maambire gũcooka gũikara mĩgũnda-inĩ yao o kũu matũũra-inĩ mao, maarĩ andũ amwe a Isiraeli, na athĩnjĩri-Ngai, na Alawii, na ndungata cia hekarũ.
3 Àwọn tí ó wá láti Juda láti Benjamini àti láti Efraimu àti Manase tí ó ń gbé ní Jerusalẹmu jẹ́:
Andũ arĩa maatũũraga Jerusalemu kuuma Juda, na Benjamini, na Efiraimu, na Manase maarĩ:
4 Uttai ọmọ Ammihudu, ọmọ Omri, ọmọ Imri, ọmọ Bani, ìran ọmọ Peresi ọmọ Juda.
Uthai mũrũ wa Amihudu, mũrũ wa Omuri, mũrũ wa Imuri, mũrũ wa Bani wa rũciaro rwa Perezu mũrũ wa Juda.
5 Àti nínú ará Ṣilo: Asaiah àkọ́bí àti àwọn ọmọ rẹ̀.
Andũ a Shiloni maarĩ: Asaia ũrĩa warĩ irigithathi, na ariũ ake.
6 Ní ti ará Sera: Jeueli. Àwọn ènìyàn láti Juda sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́wàá.
Kuuma Zera aarĩ: Jeueli. Andũ othe a kuuma Juda maarĩ 690.
7 Àti nínú àwọn ọmọ Benjamini ni: Sallu ọmọ Meṣullamu, ọmọ Hodafiah; ọmọ Hasenuah;
Andũ a Benjamini maarĩ: Salu mũrũ wa Meshulamu, mũrũ wa Hodavia, mũrũ wa Hasenua;
8 Ibinaiah ọmọ Jerohamu; Ela ọmọ Ussi, ọmọ Mikri; àti Meṣullamu ọmọ Ṣefatia; ọmọ Reueli, ọmọ Ibinijah.
na Ibineia mũrũ wa Jerohamu; Ela mũrũ wa Uzi, mũrũ wa Mikiri; na Meshulamu mũrũ wa Shefatia, mũrũ wa Reueli, mũrũ wa Ibinija.
9 Àwọn ènìyàn láti Benjamini gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ ọ́ nínú ìran wọn nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó dín mẹ́rìnlélógójì. Gbogbo àwọn ọkùnrin yí jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé.
Andũ a kuuma Benjamini, ta ũrĩa maandĩkĩtwo maandĩko-inĩ ma njiarwa ciao, maarĩ 956. Arũme acio othe maarĩ atongoria a nyũmba ciao.
10 Ní ti àwọn àlùfáà: Jedaiah; Jehoiaribi; Jakini;
Athĩnjĩri-Ngai maarĩ: Jedaia, na Jehoiaribu, na Jakini;
11 Asariah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, olórí tí ó ń bojútó ilé Ọlọ́run;
na Azaria mũrũ wa Hilikia, mũrũ wa Meshulamu, mũrũ wa Zadoku, mũrũ wa Meraiothu, mũrũ wa Ahitubu ũrĩa warĩ mũmenyereri mũnene wa nyũmba ya Ngai;
12 Adaiah ọmọ Jerohamu, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malkiah; àti Masai ọmọ Adieli, ọmọ Jahisera, ọmọ Meṣullamu ọmọ Meṣilemiti, ọmọ Immeri.
na Adaia mũrũ wa Jerohamu, mũrũ wa Pashuru, mũrũ wa Malikija; na Maasai mũrũ wa Adieli, mũrũ wa Jahazera, mũrũ wa Meshulamu, mũrũ wa Meshilemithu, mũrũ wa Imeri.
13 Àwọn àlùfáà, tí wọ́n jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀sán ó dín méjì. Wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin, tí wọ́n lè dúró fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú ilé Ọlọ́run.
Athĩnjĩri-Ngai arĩa maarĩ atongoria a nyũmba ciao maarĩ 1,760. Maarĩ arũme maarĩ na ũhoti, na nĩ meehokeirwo gũtungata nyũmba-inĩ ya Ngai.
14 Ní ti àwọn ará Lefi: Ṣemaiah ọmọ Haṣubu, ọmọ Asrikamu, ọmọ Haṣabiah ará Merari;
Alawii maarĩ: Shemaia mũrũ wa Hashubu, mũrũ wa Azirikamu, mũrũ wa Hashabia ũrĩa Mũmerari,
15 Bakibakari, Hereṣi, Galali àti Mattaniah, ọmọ Mika, ọmọ Sikri, ọmọ Asafu;
na Bakabakari, na Hereshi, na Galali, na Matania mũrũ wa Mika, mũrũ wa Zikiri, mũrũ wa Asafu;
16 Obadiah ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni; àti Berekiah ọmọ Asa, ọmọ Elkana, tí ó ń gbé nínú àwọn ìlú àwọn ará Netofa.
na Obadia mũrũ wa Shemaia, mũrũ wa Galali, mũrũ wa Jeduthuni; na Berekia mũrũ wa Asa, mũrũ wa Elikana, arĩa maaikaraga matũũra-inĩ ma Anetofathi.
17 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà: Ṣallumu, Akkubu, Talmoni, Ahimani àti arákùnrin wọn, Ṣalumu olóyè wọn,
Arangĩri a ihingo maarĩ: Shalumu, na Akubu, na Talimoni, na Ahimani na ariũ a nyina, na Shalumu mũnene wao,
18 ti wà ní ipò ìdúró ní ẹnu-ọ̀nà ọba ní apá ìhà ìlà-oòrùn títí di àkókò yí. Wọ̀nyí ni àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà tí ó jẹ́ ti ìpàgọ́ àwọn ará Lefi.
acio maigĩtwo kĩhingo-inĩ kĩa mũthamaki mwena wa irathĩro, nginya ihinda-inĩ rĩu. Acio nĩo maarĩ arangĩri a ihingo a gĩkundi kĩa Alawii.
19 Ṣallumu ọmọ Kore ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora, àti àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀. Láti ìdílé rẹ̀ (àwọn ará Korati) ni ó dúró fún ṣíṣọ́ ìloro ẹnu-ọ̀nà àgọ́ gẹ́gẹ́ bí baba wọn ti ń dúró fún ṣíṣọ́ àbáwọlé ibùgbé Olúwa.
Shalumu mũrũ wa Kore, mũrũ wa Ebiasafu, mũrũ wa Kora, na athiritũ ake arangĩri a ihingo kuuma nyũmba yake ya Akohathu. Acio nĩo meehokeirwo ũrangĩri wa itoonyero rĩa hema o ta ũrĩa maithe mao meehokeirwo ũrangĩri wa itoonyero rĩa Gĩikaro kĩa Jehova.
20 Ní ìgbà àkọ́kọ́ Finehasi ọmọ Eleasari jẹ́ olórí fún àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà, Olúwa sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
Mahinda ma mbere Finehasi mũrũ wa Eleazaru nĩwe warũgamagĩrĩra arangĩri a ihingo, nake Jehova aarĩ hamwe nake.
21 Sekariah, ọmọ Meṣelemiah jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àbáwọlé sí àgọ́ ibi ìpàdé.
Zekaria mũrũ wa Meshelemia nĩwe warĩ mũrangĩri wa itoonyero rĩa Hema-ya-Gũtũnganwo.
22 Gbogbo rẹ̀ lápapọ̀, àwọn tí a yàn láti jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àwọn ìloro jẹ́ igba ó lé méjìlá. A ka àwọn wọ̀nyí nípa ìdílé ní ìletò wọn. Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ni a ti yàn sí ipò láti ọ̀dọ̀ Dafidi àti Samuẹli, aríran, nítorí òtítọ́ wọn.
Arĩa othe maathuurĩtwo matuĩke arangĩri a ihingo maarĩ 212. Marĩĩtwa mao nĩmandĩkirwo maandĩko-inĩ ma njiarwa ciao, matũũra-inĩ mao. Arangĩri a ihingo maigirwo o mũndũ harĩa ehokeirwo nĩ Daudi na Samũeli ũrĩa muoni-maũndũ.
23 Àwọn àti àwọn ọmọ wọn ni ó wà fún ṣíṣọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa ilé tí a pè ní àgọ́.
O ene na njiaro ciao nĩo maarũgamagĩrĩra ũrangĩri wa ihingo cia nyũmba ya Jehova, nyũmba ĩrĩa yetagwo Hema.
24 Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà wà ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin: ìlà-oòrùn, ìwọ̀-oòrùn àríwá àti gúúsù.
Arangĩri a ihingo maarĩ mĩena yothe ĩna: irathĩro, na ithũĩro, na gathigathini, na gũthini.
25 Àwọn arákùnrin wọn ní àwọn ìletò wọn ní láti wá ní àkókò dé àkókò láti pín iṣẹ́ ìsìn wọn fún àkókò ọjọ́ méje.
Ariũ a ithe wao a matũũra mao nĩmookaga rĩmwe na rĩmwe magateithania mawĩra nao ihinda rĩa mĩthenya mũgwanja.
26 Ṣùgbọ́n àwọn olórí alábojútó ẹnu-ọ̀nà mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí wọ́n jẹ́ ará Lefi ni a yàn fún àwọn iyàrá àti àwọn àpótí ìṣúra ní ilé Ọlọ́run.
No anene arĩa ana maaroraga arangĩri a ihingo, arĩa maarĩ Alawii, nĩmehokeirwo kũmenyerera tũnyũmba na igĩĩna cia nyũmba ya Ngai.
27 Wọ́n á lo gbogbo òru ní dídúró yí ilé Ọlọ́run ká, nítorí wọ́n ní láti ṣọ́ ọ, wọ́n sì ní àṣẹ sí kọ́kọ́rọ́ fún ṣíṣí i ní àràárọ̀.
Maikaraga ũtukũ wothe hakuhĩ na nyũmba ya Ngai nĩgeetha mamĩrangagĩre; na nĩo maamenyagĩrĩra cabi ya kũmĩhingũra o rũciinĩ.
28 Díẹ̀ wà ní ìdí ohun èlò tí à ń lò fún ìsìn ilé Ọlọ́run; wọn a máa kà á nígbà tí wọ́n gbé e wọlé àti nígbà tí a kó wọn jáde.
Amwe ao maarĩ amenyereri a indo iria ciatũmagĩrwo ũtungata-inĩ wa hekarũ; nĩmacitaraga ikĩrutwo na igĩcookio nyũmba thĩinĩ.
29 Àwọn mìíràn ni a yàn láti bojútó ohun èlò àti gbogbo ohun èlò ilé tí a yà sọ́tọ̀ fún Ọlọ́run, àti ìyẹ̀fun àti ọtí èso àjàrà àti òróró náà, tùràrí àti tùràrí olóòórùn dídùn.
Angĩ maaheetwo wĩra wa kũmenyerera indo cia nyũmba na indo iria ingĩ ciothe ciakoragwo handũ-harĩa-haamũre, o hamwe na mũtu, na ndibei, na maguta, na ũbani, na mahuti marĩa manungi wega.
30 Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú àwọn àlùfáà ni ó ń bojútó pípò tùràrí olóòórùn dídùn papọ̀.
No athĩnjĩri-Ngai amwe nĩo maarutaga wĩra wa gũtukania mahuti macio manungi wega.
31 Ará Lefi tí a sọ ní Mattitiah àkọ́bí ọmọkùnrin Ṣallumu ará Kora ni a yàn, tí ń ṣe alábojútó ohun tí a dín.
Mũlawii wetagwo Matithia, irigithathi rĩa Shalumu ũrĩa Mũkoora, nĩwe wehokeirwo wĩra wa gũthondeka mĩgate ya maruta.
32 Àti nínú àwọn arákùnrin wọn, nínú àwọn ọmọ Kohati tó ń ṣe ìtọ́jú àkàrà ìfihàn, láti máa pèsè rẹ̀ ní ọjọọjọ́ ìsinmi.
Ariũ a ithe amwe ao a mũhĩrĩga wa Kohathu nĩo marũgamagĩrĩra ũthondeki wa mĩgate ya kũigĩrĩrwo metha-inĩ hĩndĩ ya thabatũ.
33 Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọkùnrin, olórí àwọn ìdílé Lefi dúró nínú àgọ́ ilé Olúwa, wọn kò sì ṣe lára iṣẹ́ ìsìn yòókù nítorí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ náà lọ́sàn, lóru.
Arĩa maarĩ aini, na atongoria a nyũmba cia Alawii, maaikaraga tũnyũmba-inĩ kũu hekarũ thĩinĩ na matiarutaga mawĩra mangĩ tondũ maarĩ a kũmenyerera wĩra ũcio wao mũthenya na ũtukũ.
34 Gbogbo wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn Lefi, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Acio othe maarĩ atongoria a nyũmba cia Alawii, na anene o ta ũrĩa maandĩkĩtwo ibuku-inĩ rĩa njiarwa ciao, nao maatũũraga Jerusalemu.
35 Jeieli baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Orúkọ ìyàwó rẹ̀ a máa jẹ́ Maaka,
Jeieli ithe wa Gibeoni aatũũraga Gibeoni. Mũtumia wake eetagwo Maaka,
36 pẹ̀lú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀ jẹ́ Abdoni, tí wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu.
na mũriũ wake wa irigithathi eetagwo Abidoni, akarũmĩrĩrwo nĩ Zuru, na Kishu, na Baali, na Neri, na Nadabu,
37 Gedori, Ahio, Sekariah àti Mikiloti.
na Gedori, na Ahio, na Zekaria, na Mikilothu.
38 Mikiloti jẹ́ baba Ṣimeamu, àwọn náà ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
Mikilothu nĩwe warĩ ithe wa Shimeami. O nao maikaraga hakuhĩ na andũ ao kũu Jerusalemu.
39 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba a Saulu, àti Saulu baba a Jonatani, àti Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
Neri aarĩ ithe wa Kishu, nake Kishu aarĩ ithe wa Saũlũ, nake Saũlũ aarĩ ithe wa Jonathani, na Maliki-Shua, na Abinadabu, na Eshi-Baali.
40 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali, tí ó jẹ́ baba Mika.
Mũriũ wa Jonathani eetagwo Meribu-Baali, na nĩwe warĩ ithe wa Mika.
41 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni. Meleki, Tarea àti Ahasi.
Ariũ a Mika maarĩ: Pithoni, na Meleku, na Taharea, na Ahazu.
42 Ahasi jẹ́ baba Jada, Jada jẹ́ baba Alemeti, Asmafeti, Simri, sì Simri jẹ́ baba Mosa.
Ahazu aarĩ ithe wa Jara, nake Jara aarĩ ithe wa Alemethu, na Azimavethu, na Zimuri, nake Zimuri aarĩ ithe wa Moza.
43 Mosa jẹ́ baba Binea; Refaiah jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
Moza aarĩ ithe wa Binea, nake Refaia aarĩ mũriũ wa Binea, nake Eleasa aarĩ mũriũ wa Refaia, nake Azeli aarĩ mũriũ wa Eleasa.
44 Aseli ní ọmọ mẹ́fà, pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli Ṣeariah, Obadiah àti Hanani, gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Azeli aarĩ na ariũ atandatũ, na maya nĩmo marĩĩtwa mao: Azirikamu, na Bokeru, na Ishumaeli, na Shearia, na Obadia, na Hanani. Acio nĩo maarĩ ariũ a Azeli.

< 1 Chronicles 9 >