< 1 Chronicles 8 >

1 Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
Benjamim gerou a Belá seu primogênito, Asbel o segundo, Aará o terceiro,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
Noá o quarto, e Rafa o quinto.
3 Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
E os filhos de Belá foram: Adar, Gera, Abiúde,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
Abisua, Naamã, Aoá,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
Gera, Sefufá, e Hurão.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
E estes foram os filhos de Eúde, os quais foram os cabeças das famílias dos moradores em Geba, que foram levados cativos a Manaate:
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
Naamã, Aías, e Gera; este os levou cativos, e gerou a Uzá e a Aiúde.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
E Saaraim gerou filhos na terra de Moabe, depois que deixou a suas mulheres Husim e Baara.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
De sua mulher Hodes ele gerou a Jobabe, Zíbia, Messa, Malcã,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
Jeús, Saquias, e Mirma. Estes foram seus filhos, cabeças de famílias.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
E de Husim ele gerou a Abitube, e a Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
E os filhos de Elpaal foram: Héber, Misã, Semede (o qual edificou a Ono e a Lode com suas aldeias),
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
Assim como Berias, e Sema, que foram cabeças das famílias dos moradores de Aijalom, os quais afugentaram aos moradores de Gate.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
E Aiô, Sasaque, Jeremote,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
Zebadias, Arade, Eder;
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
Micael, Ispa, e Joá, foram filhos de Berias.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
E Zebadias, Mesulão, Hizqui, Héber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
Ismerai, Izlias, e Jobabe, foram filhos de Elpaal.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
E Jaquim, Zicri, Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
Elioenai, Ziletai, Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
Adaías, Beraías, e Sinrate, foram filhos de Simei.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
E Ispã, Héber, Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
Abdom, Zicri, Hanã,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
Hananias, Elão, Antotias,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
Ifdeias, e Penuel, foram filhos de Sasaque.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
E Sanserai, Searias, Atalias;
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
Jaaresias, Elias, e Zicri, foram filhos de Jeroão.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Estes foram cabeças de famílias, chefes segundo suas gerações; estes habitaram em Jerusalém.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
E em Gibeão habitou o pai de Gibeão; e o nome de sua mulher era Maaca;
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
E seu filho primogênito foi Abdom; depois Zur, Quis, Baal, Nadabe,
31 Gedori Ahio, Sekeri
Gedor, Aiô, Zequer,
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
E Miclote, que gerou a Simeia. Estes também habitaram perto de irmãos em Jerusalém, vizinhos a eles.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
E Ner gerou a Quis; Quis gerou a Saul, e Saul gerou a Jônatas, Malquisua, Abinadabe, e a Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
O filho de Jônatas foi Meribe-Baal, e Meribe-Baal gerou a Mica.
35 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
Os filhos de Mica foram: Pitom, Meleque, Tareia e Acaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
E Acaz gerou a Jeoada; e Jeoada gerou a Alemete, a Azmavete, e a Zinri; e Zinri gerou a Moza.
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
E Moza gerou a Bineá, cujo filho foi Rafa, cujo filho foi Eleasá, cujo filho foi Azel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Azel teve seis filhos, cujos nomes foram: Azricão, Bocru, Ismael, Searias, Obadias, e Hanã; todos estes foram filhos de Azel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
E os filhos de Eseque, seu irmão, foram: Ulão seu primogênito, Jeús o segundo, e Elifelete o terceiro.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.
E os filhos de Ulão foram guerreiros valentes, hábeis flecheiros; e tiveram muitos filhos e netos, cento e cinquenta. Todos estes foram dos filhos de Benjamim.

< 1 Chronicles 8 >