< 1 Chronicles 8 >
1 Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
E Benjamin gerou a Bela, seu primogenito, a Asbel o segundo, e a Ahrah o terceiro,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
A Noha o quarto, e a Rapha o quinto.
3 Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
E Bela teve estes filhos: Addar, e Gera, e Abihud,
E Abisua, e Naaman, e Ahoah,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
E Gera, e Sephuphan, e Huram.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
E estes foram os filhos de Ehud: estes foram chefes dos paes dos moradores de Geba; e os transportaram a Manahath,
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
E a Naaman, e Ahias, e Gera; a estes transportou; e gerou a Uzza e a Ahihud.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
E Saharaim (depois de os enviar), na terra de Moab, gerou filhos d'Husim e Baara, suas mulheres.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
E de Hodes, sua mulher, gerou a Jobab, e a Zibia, e a Mesa, e a Malcam,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
E a Jeus, e a Sachias, e a Mirma: estes foram seus filhos, chefes dos paes.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
E de Husim gerou a Abitud e a Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
E foram os filhor d'Elpaal: Eber, e Misam, e Semer: este edificou a Ono e a Lod e os logares da sua jurisdicção.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
E Beria e Sema foram cabeças dos paes dos moradores de Aijalon; estes afugentaram os moradores de Gath.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
E Ahio, e Sasak, e Jeremoth,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
E Zebadias, e Arad, e Eder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
E Michael, e Ispa, e Joha, foram filhos de Beria:
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
E Zebadias, e Mesullam, e Hizki, e Heber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
E Ismerai, e Izlias, e Jobab, filhos de Elpaal:
E Jakim, e Zichri, e Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
E Elienai, e Zillethai, e Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
E Adaias, e Beraias, e Simrath, filhos de Simei:
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
E Ispan, e Eber, e Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
E Abdon, e Zichri, e Hanan,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
E Hananias, e Elam, e Anthothija,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
E Iphdias, e Penuel, filhos de Sasak:
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
E Samserai, e Seharias, e Athalias,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
E Jaaresias, e Elias, e Zichri, filhos de Jeroham.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Estes foram chefes dos paes, segundo as suas gerações, e estes habitaram em Jerusalem.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
E em Gibeon habitou o pae de Gibeon: e era o nome de sua mulher Maaka;
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
E seu filho primogenito Abdon; depois Zur, e Kis, e Baal, e Nadab,
E Gedor, e Ahio, e Zecher.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
E Mikloth gerou a Simea: e tambem estes, defronte de seus irmãos, habitaram em Jerusalem com seus irmãos.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
E Ner gerou a Kis, e Kis gerou a Saul; e Saul gerou a Jonathan, e a Malchi-sua, e a Abinadab, e a Es-baal.
34 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
E filho de Jonathan foi Merib-baal: e Merib-baal gerou a Micha.
35 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
E os filhos de Micha foram: Pithon, e Melech, e Tarea, e Achaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
E Achaz gerou a Joadda, e Joadda gerou a Alemeth, e a Azmaveth, e a Zimri; e Zimri gerou a Mosa,
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
E Mosa gerou a Bina, cujo filho foi Rapha, cujo filho foi Elasa, cujo filho foi Asel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
E teve Asel seis filhos, e estes foram os seus nomes: Azrikam, e Boceru, e Ishmael, e Searias, e Obadias, e Hanan: todos estes foram filhos de Asel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
E os filhos de Esek, seu irmão: Ulam, seu primogenito, Jeus o segundo, e Eliphelet o terceiro.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.
E foram os filhos de Ulam varões heroes, valentes, e frecheiros destros; e tiveram muitos filhos, e filhos de filhos, cento e cincoenta: todos estes foram dos filhos de Benjamin.