< 1 Chronicles 8 >

1 Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
Beniamin autem genuit Bale primogenitum suum, Asbel secundum, Ahara tertium,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
Nohaa quartum, et Rapha quintum.
3 Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
Fueruntque filii Bale: Addar, et Gera, et Abiud,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
Abisue quoque et Naaman, et Ahoe,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
sed et Gera, et Sephuphan, et Huram.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
Hi sunt filii Ahod, principes cognationum habitantium in Gabaa, qui translati sunt in Manahath.
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
Naaman autem, et Achia, et Gera ipse transtulit eos, et genuit Osa, et Ahiud.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
Porro Saharaim genuit in regione Moab, postquam dimisit Husim, et Bara uxores suas.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
Genuit autem de Hodes uxore sua Iobab, et Sebia, et Mosa, et Molchom,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
Iehus quoque, et Sechia, et Marma. hi sunt filii eius principes in familiis suis.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
Mehusim vero genuit Abitob, et Elphaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
Porro filii Elphaal: Heber, et Misaam, et Samad: hic aedificavit Ono, et Lod, et filias eius.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
Baria autem, et Sama principes cognationum habitantium in Aialon: hi fugaverunt habitatores Geth.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
Et Ahio, et Sesac, et Ierimoth,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
et Zabadia, et Arod, et Heder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
Michael quoque, et Iespha, et Ioha filii Baria.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
Et Zabadia, et Mosollam, et Hezeci, et Heber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
et Iesamari, et Iezlia, et Iobab filii Elphaal,
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
et Iacim, et Zechri, et Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
et Elioenai, et Selethai, et Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
et Adaia, et Baraia, et Samarath filii Semei.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
Et Iespham, et Heber, et Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
et Abdon, et Zechri, et Hanan,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
et Hanania, et Aelam, et Anathothia,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
et Iephdaia, et Phanuel filii Sesac.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
et Samsari, et Sohoria, et Otholia,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
et Iersia, et Elia, et Zechri, filii Ieroham.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
hi patriarchae, et cognationum principes, qui habitaverunt in Ierusalem.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
In Gabaon autem habitaverunt Abigabaon, et nomen uxoris eius Maacha:
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
filiusque eius primogenitus Abdon, et Sur, et Cis, et Baal, et Nadab.
31 Gedori Ahio, Sekeri
Gedor quoque, et Ahio, et Zacher, et Macelloth:
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
et Macelloth genuit Samaa: habitaveruntque ex adverso fratrum suorum in Ierusalem cum fratribus suis.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
Ner autem genuit Cis, et Cis genuit Saul. Porro Saul genuit Ionathan, et Melchisua, et Abinadab, et Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
Filius autem Ionathan, Meribbaal: et Meribbaal genuit Micha.
35 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
Filii Micha, Phithon, et Melech, et Tharaa, et Ahaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
et Ahaz genuit Ioada: et Ioada genuit Alamath, et Azmoth, et Zamri: porro Zamri genuit Mosa,
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
et Mosa genuit Banaa, cuius filius fuit Rapha, de quo ortus est Elasa, qui genuit Asel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Porro Asel sex filii fuerunt his nominibus, Ezricam, Bocru, Ismahel, Saria, Obdia, et Hanan. omnes hi filii Asel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
Filii autem Esec fratris eius, Ulam primogenitus, et Iehus secundus, et Eliphalet tertius.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.
Fueruntque filii Ulam viri robustissimi, et magno robore tendentes arcum: et multos habentes filios ac nepotes, usque ad centum quinquaginta millia. Omnes hi, filii Beniamin.

< 1 Chronicles 8 >