< 1 Chronicles 8 >

1 Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
Benjamini nĩwe warĩ ithe wa Bela, mũriũ wake wa irigithathi; Ashibeli aarĩ mũriũ wa keerĩ, nake Ahara wa gatatũ,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
nake Noha wa kana, nake Rafa wa gatano.
3 Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
Ariũ a Bela maarĩ: Adari, na Gera, na Abihudi,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
na Abishua, na Naamani, na Ahoa,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
na Gera, na Shefufani, na Huramu.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
Aya nĩo maarĩ njiaro cia Ehudu, arĩa maarĩ atongoria a nyũmba cia arĩa maatũũraga Geba, na nĩo maathaamĩirio Manahathu:
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
Naamani, na Ahija, na Gera ũrĩa wamathaamirie, na nĩwe warĩ ithe wa Uza na Ahihudu.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
Shaharaimu nĩaciarĩirwo ciana kũu Moabi thuutha wa gũte atumia ake Hushimu na Baara.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
Mũtumia wake Hodeshu akĩmũciarĩra ciana ici: Jobabu, na Zibia, na Mesha, na Malikamu,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
na Jeuzu, na Shakia, na Mirima. Acio nĩo maarĩ ariũ ake, na maarĩ atongoria a nyũmba ciao.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
Mũtumia wake Hushimu akĩmũciarĩra Ahitubu na Elipaali.
12 Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
Ariũ a Elipaali maarĩ: Eberi, na Mishamu, na Shemedi (ũrĩa wakire Ono, o na Lodi na matũũra marĩa maakũrigiicĩirie),
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
na Beria, na Shema arĩa maarĩ atongoria a nyũmba cia arĩa maatũũraga Aijaloni, na nĩo maingatire andũ arĩa maatũũraga Gathu.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
Ahio, na Shashaka, na Jeremothu,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
na Zebadia, na Aradi, na Ederi,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
na Mikaeli, na Ishipa, na Joha maarĩ ariũ a Beria.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
Zebadia, na Meshulamu, na Hiziki, na Heberi,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
na Ishimerai, na Izilia, na Jababu maarĩ ariũ a Elipaali.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
Jakimu, na Zikiri, na Zabedi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
na Elienai, na Zilethai, na Elieli,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
na Adaia, na Beraia, na Shimirathu maarĩ ariũ a Shimei.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
Ishipani, na Eberi, na Elieli,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
na Abidoni, na Zikiri, na Hanani,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
na Hanania, na Elamu, na Anithothija,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
na Ifĩdeia, na Penueli maarĩ ariũ a Shashaka.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
Shamusherai, na Sheharia, na Athalia,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
na Jaareshia, na Elija, na Zikiri maarĩ ariũ a Jerohamu.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Aya othe maarĩ atongoria a nyũmba o na anene, ta ũrĩa maandĩkĩtwo maandĩko-inĩ ma njiarwa ciao, na maaikaraga Jerusalemu.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
Jeieli ithe wa Gibeoni aatũũraga Gibeoni. Mũtumia wake eetagwo Maaka,
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
na mũriũ wake wa irigithathi eetagwo Abidoni, akarũmĩrĩrwo nĩ Zuru, na Kishu, na Baali, na Neri, na Nadabu,
31 Gedori Ahio, Sekeri
na Gedori, na Ahio, na Zekeri,
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
na Mikilothu ũrĩa warĩ ithe wa Shimea. O nao maaikaraga hakuhĩ na andũ ao kũu Jerusalemu.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
Neri aarĩ ithe wa Kishu, nake Kishu aarĩ ithe wa Saũlũ. Saũlũ aarĩ ithe wa Jonathani
34 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
Mũriũ wa Jonathani: eetagwo Meribu-Baali, na nĩwe warĩ ithe wa Mika.
35 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
Ariũ a Mika maarĩ: Pithoni, na Meleku, na Tarea, na Ahazu.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
Ahazu aarĩ ithe wa Jehoada, nake Jehoada aarĩ ithe wa Alemethu, na Azamavethu, na Zimuri; nake Zimuri aarĩ ithe wa Moza.
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
Moza aarĩ ithe wa Binea; nake Rafa aarĩ mũriũ wa Binea, nake Eleasa aarĩ mũriũ wa Rafa, nake Azeli aarĩ mũriũ wa Eleasa.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Azeli aarĩ na ariũ atandatũ, na maya nĩmo marĩĩtwa mao: Azirikamu, na Bokeru, na Ishumaeli, na Shearia, na Obadia, na Hanani. Acio nĩo maarĩ ariũ a Azeli.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
Ariũ a Esheku, mũrũ wa nyina, maarĩ: Ulamu irigithathi rĩake, na Jeushu wa keerĩ, na Elifeleti wa gatatũ.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.
Ariũ a Ulamu maarĩ njamba cia ita, na nĩmamenyete gũtũmĩra ũta. Maarĩ na ariũ aingĩ o na ciana cia ciana ciao, na othe maarĩ 150. Acio othe nĩo maarĩ njiaro cia Benjamini.

< 1 Chronicles 8 >