< 1 Chronicles 8 >

1 Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
Benjamin aber zeugete Bela, seinen ersten Sohn, Asbal den andern, Ahrah den dritten,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
Noha den vierten, Rapha den fünften.
3 Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
Und Bela hatte Kinder: Addar, Gera, Abihud,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
Abisua, Naeman, Ahoah,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
Gera, Sephuphan und Huram.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
Dies sind die Kinder Ehuds, die da Häupter waren der Väter unter den Bürgern zu Geba und zogen weg gen Manahath:
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
nämlich Naeman, Ahia und Gera, derselbe führete sie weg; und er zeugete Usa und Ahihud.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
Und Saharaim zeugete im Lande Moab (da er jene von sich gelassen hatte) von Husim und Baera, seinen Weibern.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
Und er zeugete von Hodes, seinem Weibe: Jobab, Zibja, Mesa, Malcham,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
Jeuz, Sachja und Mirma. Das sind seine Kinder, Häupter der Väter.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
Von Husim aber zeugete er Abitob und Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
Die Kinder aber Elpaals waren: Eber, Miseam und Samed. Derselbe bauete Ono und Lod und ihre Töchter.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
Und Bria und Sama waren Häupter der Väter unter den Bürgern zu Ajalon; sie verjagten die zu Gath.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
Ahjo aber, Sasak, Jeremoth,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
Sebadja, Arad, Ader,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
Michael, Jespa und Joha; das sind Kinder Brias.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
Sebadja, Mesullam, Hiski, Heber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
Jesmerai, Jeslia, Jobab; das sind Kinder Elpaals.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
Jakim, Sichri, Sabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
Elioenai, Zilthai, Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
Adaja, Braja und Simrath; das sind die Kinder Simeis.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
Jespan, Eber, Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
Abdon, Sichri, Hanan,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
Hananja, Elam, Anthothja,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
Jephdeja und Pnuel; das sind die Kinder Sasaks.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
Samserai, Seharja, Athalja,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
Jaeresja, Elia und Sichri; das sind Kinder Jerohams.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Das sind die Häupter der Väter ihrer Geschlechter, die wohneten zu Jerusalem.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
Aber zu Gibeon wohnete der Vater Gibeons; und sein Weib hieß Maecha.
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
Und sein erster Sohn war Abdon, Zur, Kis, Baal, Nadab,
31 Gedori Ahio, Sekeri
Gedor, Ahjo und Secher.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
Mikloth aber zeugete Simea; und sie wohneten gegen ihren Brüdern zu Jerusalem mit ihnen.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
Ner zeugete Kis. Kis zeugete Saul. Saul zeugete Jonathan, Malchisua, Abinadab und Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
Der Sohn aber Jonathans war Meribaal. Meribaal zeugete Micha.
35 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
Die Kinder Michas waren: Pithon, Melech, Thaerea und Ahas.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
Ahas aber zeugete Joadda. Joadda zeugete Alemeth, Asmaveth und Simri. Simri zeugete Moza.
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
Moza zeugete Binea; des Sohn war Rapha; des Sohn war Eleasa; des Sohn war Azel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Azel aber hatte sechs Söhne, die hießen: Esrikam, Bochru, Jesmael, Searja, Obadja, Hanan. Die waren alle Söhne Azels.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
Die Kinder Eseks, seines Bruders, waren: Ulam, sein erster Sohn, Jeus der andere, Eliphelet der dritte.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.
Die Kinder aber Ulams waren gewaltige Leute und geschickt mit Bogen; und hatten viele Söhne und Sohnes Söhne, hundertundfünfzig. Die sind alle von den Kindern Benjamins.

< 1 Chronicles 8 >