< 1 Chronicles 8 >

1 Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
Benjamin zeugte als seinen Erstgeborenen Bela, als zweiten Asbel, als dritten Achrach,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
als vierten Nocha und als fünften Rapha.
3 Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
Bela hatte zu Söhnen Addar, Gera, Abihud,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
Abisu, Naaman, Achoch,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
Gera, Sephuphan und Churam.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
Dies sind Achuds Söhne. Diese sind die Familienhäupter der Einwohner Gebas. Man führte sie gefangen nach Manachat.
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
Naaman, Achia und Gera hat er fortgeführt, nachdem jener Uzza und Achichud gezeugt hatte.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
Sacharaim zeugte in Moabs Gefilde, nachdem er seine Weiber Chusim und Baara entlassen hatte.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
Er zeugte mit seinem Weibe Chodes den Jobab, Sibja, Mesa, Malkam,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
Jëus, Sokja und Mirma. Dies sind seine Söhne, Familienhäupter.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
Mit Chusim hatte er Abitub und Elpaal gezeugt.
12 Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
Elpaals Söhne sind Eber, Misam und Semer. Dieser baute Ono, ebenso Lod mit seinen Tochterorten.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
Beria und Sema sind die Familienhäupter der Einwohner Ajjalons. Sie haben die Bewohner von Gat vertrieben.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
Berias Söhne sind Achjo, Sasak, Jeremot,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
Zebadja, Arad, Ader,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
Mikael, Ispa und Jocha.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
Elpaals Söhne sind Zebadja, Mesullam, Chizki, Cheber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
Ismere, Izlia und Jobab.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
Simeis Söhne sind Jakim, Zikri, Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
Elienai, Silletai, Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
Adaja, Beraja und Simrat.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
Sasaks Söhne sind Ispan, Eber, Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
Abdon, Zikri, Chanan,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
Chananja, Elam, Antotia,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
lphdaja und Penuel.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
Jerochams Söhne sind Samserai, Secharja, Atalja,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
Jaaresja, Elia und Zikri.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
Dies sind in ihren Sippen die Familienhäupter. Als Häupter haben sie zu Jerusalem gewohnt.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
Zu Gibeon wohnten der Vater Gibeons und sein Weib namens Maaka.
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
Sein erstgeborener Sohn ist Abdon, dann Sur, Kis, Baal, Nadab,
31 Gedori Ahio, Sekeri
Gedor, Achjo und Zeker.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
Miklot hat Sima gezeugt. Auch sie wohnten in Jerusalem bei ihren Brüdern, diesen gegenüber.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
Ner zeugte Kis und Kis den Saul und Saul den Jonatan, Malkisua, Abinadab und Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
Jonatans Sohn ist Meribbaal, und Meribbaal zeugte Mika.
35 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
Mikas Söhne sind Piton, Melek, Tare und Achaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
Achaz zeugte Joadda und Joadda den Alemet, Azmavet und Zimri und Zimri den Mosa.
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
Mosa zeugte den Bina. Dessen Sohn ist Rapha, dessen Sohn Elasa und dessen Sohn Asel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Asel hatte sechs Söhne. Dies sind ihre Namen: Azrikam, sein Erstgeborener, Ismael und Searja, Obadja und Chanan. Alle diese waren Söhne Asels.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
Seines Bruders Esek Söhne sind sein Erstgeborener Ulam, der zweite Jëus und der dritte Eliphelet.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.
Ulams Söhne waren kriegstüchtige Männer, die den Bogen spannen konnten. Sie hatten auch zahlreiche Söhne und Enkel, 150. Alle diese gehören zu den Söhnen Benjamins.

< 1 Chronicles 8 >