< 1 Chronicles 8 >

1 Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
Benjamin engendra Béla, qui fut son premier-né, Achbêl, le second, Ahrah, le troisième,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
Noha, le quatrième, et Rafa, le cinquième.
3 Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
Béla eut des fils, à savoir: Addar, Ghêra, Abihoud,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
Abichoua, Naamân, Ahoah,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
Ghêra, Chefoufân et Hourâm.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
Et voici les fils d’Ehoud: c’étaient les chefs de famille des habitants de Ghéba, qu’on déporta à Manahath,
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
Naaman, Ahiya et Ghêra c’est celui-ci qui les déporta. Il engendra Ouzza et Ahihoud.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
Chaharaïm engendra dans la campagne de Moab, après avoir répudié Houchim et Baara, ses femmes.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
Il eut de sa femme Hodech: Yobab, Cibia, Mêcha, Malkâm,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
Yeouç, Sakhia et Mirma. Tels furent ses fils, qui devinrent chefs de familles.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
De Houchim il avait eu Abitoub et Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
Les fils d’Elpaal furent Eber, Micheâm et Chémer. Celui-ci fut le fondateur de Ono et de Lod, avec ses dépendances.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
Berïa et Chéma, chefs des familles des habitants d’Ayyalôn, mirent en fuite les habitants de Gath.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
Ahio, Chachak, Yerêmoth,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
Zebadia, Arad, Eder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
Mikhaêl, Yichpa et Yoha étaient les fils de Berïa.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
Zebadia, Mechoullam, Hizki, Héber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
Yichmeraï, Yizlïa et Yobab étaient fils d’Elpaal.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
Yakim, Zikhri, Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
Elïênaï, Cilletaï, Elïêl,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
Adaïa, Beraya et Chimrât étaient fils de Chimeï.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
Yochpân, Eber, Elïêl,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
Abdôn, Zikhri, Hanân,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
Hanania, Elâm, Antotiya,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
Yifdeya et Penouêl étaient fils de Chachak.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
Chamcheraï, Cheharia, Atalia,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
Yaaréchia, Eliya et Zikhri étaient fils de Yeroham.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
C’Étaient les chefs de famille, chefs selon leur généalogie. Ils habitaient Jérusalem.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
A Gabaon demeuraient le "père" de Gabaon, dont la femme s’appelait Maakha,
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
son fils aîné Abdôn, Çour, Kich, Baal, Nadab,
31 Gedori Ahio, Sekeri
Ghedor, Ahio et Zékher.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
Miklôt engendra Chimea. Ceux-là aussi, à l’encontre de leurs frères, habitaient Jérusalem avec leurs frères.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
Ner engendra Kich, celui-ci Saül, celui-ci Jonathan, Malki-Choua, Abinadab et Echbaal.
34 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
Le fils de Jonathan s’appelait Merib-Baal, qui donna le jour à Mikha.
35 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
Les fils de Mikha furent: Pitôn, Mélec, Tarêa et Ahaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
Ahaz engendra Yehoadda, celui-ci Alémeth, Azmaveth et Zimri. Zimri engendra Moça,
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
celui-ci Binea, celui-ci Rafa, celui-ci Elassa, celui-ci Acêl.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
Acêl eut six fils, dont voici les noms: Azrikâm, Bokhrou, Ismaël, Chearia, Obadia et Hanân. Tous ceux-là étaient fils d’Acêl.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
Les fils de son frère Echek étaient: Oulam, l’aîné, Yeouch, le second, et Elifélet, le troisième.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.
Les fils d’Oulam étaient des hommes d’armes, maniant l’arc. Ils eurent nombre de fils et de petits-fils, en tout cent cinquante. Tous ceux-là étaient des Benjaminites.

< 1 Chronicles 8 >