< 1 Chronicles 8 >

1 Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
And Benjamin begat Bela his firstborn, Ashbel the second, and Aharah the third;
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
Nohah the fourth, and Rapha the fifth.
3 Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
And Bela had sons, Addar, and Gera, and Abihud;
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
and Abishua, and Naaman, and Ahoah;
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
and Gera, and Shephuphan, and Huram.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
And these are the sons of Ehud: these are the heads of fathers’ [houses] of the inhabitants of Geba, and they carried them captive to Manahath:
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
and Naaman, and Ahijah, and Gera, he carried them captive; and he begat Uzza and Ahihud:
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
And Shaharaim begat children in the field of Moab, after he had sent them away; Hushim and Baara were his wives.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
And he begat of Hodesh his wife, Jobab, and Zibia, and Mesha, and Malcam;
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
and Jeuz, and Shachia, and Mirmah. These were his sons, heads of fathers’ [houses].
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
And of Hushim he begat Abitub and Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
And the sons of Elpaal; Eber, and Misham, and Shemed, who built Ono and Lod, with the towns thereof:
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
and Beriah, and Shema, who were heads of fathers’ [houses] of the inhabitants of Aijalon, who put to flight the inhabitants of Gath;
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
and Ahio, Shashak, and Jeremoth;
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
and Zebadiah, and Arad, and Eder;
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
and Michael, and Ishpah, and Joha, the sons of Beriah;
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
and Zebadiah, and Meshullam, and Hizki, and Heber;
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
and Ishmerai, and Izliah, and Jobab, the sons of Elpaal;
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
and Jakim, and Zichri, and Zabdi;
20 Elienai, Siletai, Elieli,
and Elienai, and Zillethai, and Eliel;
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
and Adaiah, and Beraiah, and Shimrath, the sons of Shimei;
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
and Ishpan, and Eber, and Eliel;
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
and Abdon, and Zichri, and Hanan;
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
and Hananiah, and Elam, and Anthothijah;
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
and Iphdeiah, and Penuel, and sons of Shashak;
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
and Shamsherai, and Shehariah, and Athaliah;
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
and Jaareshiah, and Elijah, and Zichri, the sons of Jeroham.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
These were heads of fathers’ [houses] throughout their generations, chief men: these dwelt in Jerusalem.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
And in Gibeon there dwelt the father of Gibeon, [Jeiel], whose wife’s name was Maacah:
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
and his firstborn son Abdon, and Zur, and Kish, and Baal, and Nadab;
31 Gedori Ahio, Sekeri
and Gedor, and Ahio, and Zecher.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
And Mikloth begat Shimeah. And they also dwelt with their brethren in Jerusalem, over against their brethren.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
And Ner begat Kish; and Kish begat Saul; and Saul begat Jonathan, and Malchi-shua, and Abinadab, and Eshbaal.
34 Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
And the son of Jonathan was Merib-baal; and Merib-baal begat Micah.
35 Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
And the sons of Micah; Pithon, and Melech, and Tarea, and Ahaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
And Ahaz begat Jehoaddah; and Jehoaddah begat Alemeth, and Azmaveth, and Zimri; and Zimri begat Moza:
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
And Moza begat Binea; Raphah was his son, Eleasah his son, Azel his son:
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
And Azel had six sons, whose names are these; Azrikam, Bocheru, and Ishmael, and Sheariah, and Obadiah, and Hanan. All these were the sons of Azel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
And the sons of Eshek his brother; Ulam his firstborn, Jeush the second, and Eliphelet the third.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.
And the sons of Ulam were mighty men of valour, archers, and had many sons, and sons’ sons, an hundred and fifty. All these were of the sons of Benjamin.

< 1 Chronicles 8 >