< 1 Chronicles 6 >

1 Àwọn ọmọ Lefi: Gerṣoni, Kohati àti Merari.
Los hijos de Leví: Gersón, Coat y Merari.
2 Àwọn ọmọ Kohati: Amramu, Isari, Hebroni, àti Usieli.
Y los hijos de Coat: Amram, Izhar, Hebrón y Uziel.
3 Àwọn ọmọ Amramu: Aaroni, Mose àti Miriamu. Àwọn ọmọkùnrin Aaroni: Nadabu, Abihu, Eleasari àti Itamari.
Y los hijos de Amram: Aarón, Moisés y María. Y los hijos de Aarón: Nadab, Abiú, Eleazar e Itamar.
4 Eleasari jẹ́ baba Finehasi, Finehasi baba Abiṣua
Eleazar fue el padre de Finees; Finees fue el padre de Abisua;
5 Abiṣua baba Bukki, Bukki baba Ussi,
Y Abisúa fue el padre de Buqui, y Buqui fue el padre de Uzi,
6 Ussi baba Serahiah, Serahiah baba Meraioti,
Y Uzi fue el padre de Zeraias, y Zeraias fue el padre de Meraiot;
7 Meraioti baba Amariah, Amariah baba Ahitubu
Meraiot fue el padre de Amarías, y Amarías fue el padre de Ahitob,
8 Ahitubu baba Sadoku, Sadoku baba Ahimasi,
Y Ahitob fue el padre de Sadoc, y Sadoc fue el padre de Ahimaas,
9 Ahimasi baba Asariah, Asariah baba Johanani,
Y Ahimaas fue el padre de Azarías, y Azarías fue el padre de Johanán.
10 Johanani baba Asariah. (Òhun ni ó sìn gẹ́gẹ́ bí àlùfáà nínú ilé Olúwa tí Solomoni kọ́ sí Jerusalẹmu).
Y Johanan fue el padre de Azarías, fue sacerdote en él templo que Salomón construyó en Jerusalén:
11 Asariah baba Amariah Amariah baba Ahitubu
Y Azarías fue el padre de Amarías, y Amarías fue el padre de Ahitob.
12 Ahitubu baba Sadoku. Sadoku baba Ṣallumu,
Y Ahitob fue el padre de Sadoc, y Sadoc fue el padre de Salum,
13 Ṣallumu baba Hilkiah, Hilkiah baba Asariah,
Y Salum fue el padre de Hilcías, y Hilcías fue el padre de Azarías,
14 Asariah baba Seraiah, pẹ̀lú Seraiah baba Josadaki.
Y Azarías fue el padre de Seraías, y Seraías fue el padre de Josadac;
15 A kó Josadaki lẹ́rú nígbà tí Olúwa lé Juda àti Jerusalẹmu kúrò ní ìlú nípasẹ̀ Nebukadnessari.
Y Josadac fue llevado cautivo se puso cuando el Señor se desterró a Judá y a Jerusalén de la mano de Nabucodonosor.
16 Àwọn ọmọ Lefi: Gerṣoni, Kohati àti Merari.
Los hijos de Leví. Gerson, Coat y Merari.
17 Wọ̀nyí ni àwọn orúkọ àwọn ọmọ Gerṣoni: Libni àti Ṣimei.
Y estos son los nombres de los hijos de Gersón: Libni y Simei.
18 Àwọn ọmọ Kohati: Amramu, Isari, Hebroni àti Usieli.
Y los hijos de Coat fueron Amram, Izhar, Hebrón y Uziel.
19 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi. Wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ará Lefi tí a kọ ní ṣísẹ̀-n-tẹ̀lé gẹ́gẹ́ bí baba wọn.
Los hijos de Merari: Mahli y Musi. Y estas son las familias de los levitas enumerados por los nombres de sus padres.
20 Ti Gerṣoni: Libni ọmọkùnrin rẹ̀, Jahati. Ọmọkùnrin rẹ̀, Simma ọmọkùnrin rẹ̀,
De Gersón: Libni su hijo, Jahath su hijo, Zima su hijo,
21 Joah ọmọkùnrin rẹ̀, Iddo ọmọkùnrin rẹ̀, Sera ọmọkùnrin rẹ̀ àti Jeaterai ọmọkùnrin rẹ̀.
Joa su hijo, Ido su hijo, Zera su hijo, Jeatrai su hijo.
22 Àwọn ìran ọmọ Kohati: Amminadabu ọmọkùnrin rẹ̀, Kora ọmọkùnrin rẹ̀, Asiri ọmọkùnrin rẹ̀.
Los hijos de Coat: Aminadab su hijo, Core su hijo, Asir su hijo,
23 Elkana ọmọkùnrin rẹ̀, Ebiasafi ọmọkùnrin rẹ̀, Asiri ọmọkùnrin rẹ̀.
Elcana su hijo, Ebiasaf su hijo, Asir su hijo,
24 Tahati ọmọkùnrin rẹ̀, Urieli ọmọkùnrin rẹ̀, Ussiah ọmọkùnrin rẹ̀ àti Saulu ọmọkùnrin rẹ̀.
Tahat su hijo, Uriel su hijo, Uzías su hijo, Saúl su hijo.
25 Àwọn ìran ọmọ Elkana: Amasai, Ahimoti
Y los hijos de Elcana: Amasai y Ahimot.
26 Elkana ọmọ rẹ̀, Sofai ọmọ rẹ̀ Nahati ọmọ rẹ̀,
Elcana su hijo: Zofai su hijo, Nahat su hijo,
27 Eliabu ọmọ rẹ̀, Jerohamu ọmọ rẹ̀, Elkana ọmọ rẹ̀ àti Samuẹli ọmọ rẹ̀.
Eliab su hijo, Jeroham su hijo, Elcana su hijo, Samuel su hijo.
28 Àwọn ọmọ Samuẹli: Joẹli àkọ́bí àti Abijah ọmọ ẹlẹ́ẹ̀kejì.
Y los hijos de Samuel: Joel, el mayor, y el segundo Abías.
29 Àwọn ìran ọmọ Merari: Mahili, Libni ọmọ rẹ̀. Ṣimei ọmọ rẹ̀, Ussa ọmọ rẹ̀.
Los hijos de Merari: Mahli, Libni su hijo, Simei su hijo, Uza su hijo,
30 Ṣimea ọmọ rẹ̀, Haggiah ọmọ rẹ̀ àti Asaiah ọmọ rẹ̀.
Simea su hijo, Haguia su hijo, Asaias su hijo.
31 Èyí ní àwọn ọkùnrin Dafidi tí a fi sí ìdí orin nínú ilé Olúwa lẹ́yìn tí àpótí ẹ̀rí ti wá láti sinmi níbẹ̀.
Y estos son los que David hizo responsables de la música en el templo del Señor, después de que se colocó allí el cofre del pacto.
32 Wọ́n jíṣẹ́ pẹ̀lú orin níwájú àgọ́ ìpàdé títí tí Solomoni fi kọ́ ilé Olúwa ní Jerusalẹmu. Wọ́n ṣe iṣẹ́ ìsìn wọn ní ìbámu pẹ̀lú ìlànà tí a fi lélẹ̀ fún wọn.
Ellos adoraron con cantos ante él templo del tabernáculo de reunión, hasta que Salomón levantó el templo del Señor en Jerusalén; y tomaron sus lugares para su trabajo conforme a su costumbre.
33 Wọ̀nyí ni àwọn ọkùnrin tí ó sìn pẹ̀lú ọmọ wọn. Láti ọ̀dọ̀ àwọn ará Kohati: Hemani olùkọrin, ọmọ Joẹli, ọmọ Samuẹli,
Y estos son los que hicieron este trabajo, y sus hijos. De los hijos de él cantor, el hijo de Joel, el hijo de Samuel,
34 ọmọ Elkana, ọmọ Jerohamu, ọmọ Elieli, ọmọ Toha,
El hijo de Elcana, el hijo de Jeroham, el hijo de Eliel, el hijo de Toa,
35 ọmọ Sufu, ọmọ Elkana, ọmọ Mahati, ọmọ Amasai,
El hijo de Zuf, el hijo de Elcana, el hijo de Mahat, el hijo de Amasai,
36 ọmọ Elkana, ọmọ Joẹli, ọmọ Asariah, ọmọ Sefaniah,
El hijo de Elcana, el hijo de Joel, el hijo de Azarías, el hijo de Sofonías,
37 ọmọ Tahati, ọmọ Asiri, ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora,
El hijo de Tahat, el hijo de Asir, el hijo de Ebiasaf, el hijo de Coré,
38 ọmọ Isari, ọmọ Kohati, ọmọ Lefi, ọmọ Israẹli;
El hijo de Izhar, el hijo de Coat, el hijo de Leví, el hijo de Israel.
39 Hemani sì darapọ̀ mọ́ Asafu, ẹni tí o sìn ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀: Asafu ọmọ Berekiah, ọmọ Ṣimea,
Y su hermano Asaf, cuyo lugar estaba a su derecha, Asaf, hijo de Berequías, hijo de Simea,
40 ọmọ Mikaeli, ọmọ Baaseiah, ọmọ Malkiah
El hijo de Micael, el hijo de Baasías, el hijo de Malquías,
41 ọmọ Etini, ọmọ Sera, ọmọ Adaiah,
El hijo de Etni, el hijo de Zera, el hijo de Adaía,
42 ọmọ Etani, ọmọ Simma, ọmọ Ṣimei,
El hijo de Etán, el hijo de Zima, el hijo de Simei,
43 ọmọ Jahati, ọmọ Gerṣoni, ọmọ Lefi;
El hijo de Jahat, el hijo de Gersón, el hijo de Leví.
44 láti ìbákẹ́gbẹ́ wọn, àwọn ará Merari wà ní ọwọ́ òsì rẹ̀: Etani ọmọ Kiṣi, ọmọ Abdi, ọmọ Malluki,
Y a la izquierda, sus hermanos, los hijos de Merari: Ethan, el hijo de Quisi, el hijo de Abdi, el hijo de Maluc,
45 ọmọ Haṣabiah, ọmọ Amasiah, ọmọ Hilkiah,
El hijo de Hasabías, el hijo de Amasías, el hijo de Hilcías,
46 ọmọ Amisi, ọmọ Bani, ọmọ Ṣemeri,
El hijo de Amsi, el hijo de Bani, el hijo de Semer,
47 ọmọ Mahili, ọmọ Muṣi, ọmọ Merari, ọmọ Lefi.
El hijo de Mahli, el hijo de Musi, el hijo de Merari, el hijo de Leví.
48 Àwọn Lefi ẹgbẹ́ wọn ni wọn yan àwọn iṣẹ́ yòókù ti àgọ́ fún, èyí tí í ṣe ilé Ọlọ́run.
Y sus hermanos, los levitas, fueron responsables de todo el servicio del templo de Dios.
49 Ṣùgbọ́n Aaroni àti àwọn ìran ọmọ rẹ̀ jẹ́ àwọn tí ó gbé ọrẹ kalẹ̀ lórí pẹpẹ ẹbọ sísun àti lórí pẹpẹ tùràrí ní ìbátan pẹ̀lú gbogbo ohun tí a ṣe ní Ibi Mímọ́ Jùlọ. Ṣíṣe ètùtù fún Israẹli, ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run ti pàṣẹ.
Pero Aarón y sus hijos hicieron ofrendas sobre el altar de la ofrenda quemada, y sobre el altar del incienso, se ocupaban de todo el servicio del Lugar Santísimo, y de obtener el perdón del los pecados de Israel, haciendo todo lo que Moisés ordenó, el siervo de Dios.
50 Wọ̀nyí ni àwọn ìránṣẹ́ Aaroni: Eleasari ọmọ rẹ̀, Finehasi ọmọ rẹ̀, Abiṣua ọmọ rẹ̀,
Y estos son los hijos de Aarón: Eleazar su hijo, Finees, Abisua,
51 Bukki ọmọ rẹ̀, Ussi ọmọ rẹ̀, Serahiah ọmọ rẹ̀,
Buqui, Uzi, Zeraias,
52 Meraioti ọmọ rẹ̀, Amariah ọmọ rẹ̀, Ahitubu ọmọ rẹ̀,
Meraiot su hijo, Amarías su hijo, Ahitob su hijo,
53 Sadoku ọmọ rẹ̀ àti Ahimasi ọmọ rẹ̀.
Sadoc su hijo, Ahimaas su hijo.
54 Wọ̀nyí ni ibùgbé wọn tí a pín fún wọn gẹ́gẹ́ bí agbègbè wọn (tí a fi lé àwọn ìran ọmọ Aaroni lọ́wọ́ tí ó wá láti ẹ̀yà Kohati, nítorí kèké alákọ́kọ́ jẹ́ tiwọn).
Ahora, estos son sus lugares de residencia, los límites dentro de los cuales debían levantar sus tiendas: a los hijos de Aarón, de las familias de los coatitas, porque tenían la primera selección,
55 A fún wọn ní Hebroni ní Juda pẹ̀lú àyíká pápá oko tútù ilẹ̀ rẹ̀.
A ellos les dieron a Hebrón y sus alrededores en la tierra de Judá;
56 Ṣùgbọ́n àwọn pápá àti ìletò tí ó yí ìlú ńlá náà ká ni a fi fún Kalebu ọmọ Jefunne.
Pero el campo abierto de la ciudad y los pequeños lugares que lo rodeaban le dieron a Caleb, el hijo de Jefone.
57 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìran ọmọ Aaroni ni a fún ní Hebroni (ìlú ti ààbò), àti Libina, Jattiri, Eṣitemoa,
Y a los hijos de Aarón dieron a Hebrón, la ciudad de refugio, y Libna con sus alrededores, y Jatir, y Estemoa con sus alrededores.
58 Hileni, Debiri,
E Hilen con sus alrededores, Debir con sus alrededores,
59 Aṣani, Jutta àti Beti-Ṣemeṣi lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ rẹ̀.
Y Asán con sus alrededores, y Bet-semes con sus alrededores;
60 Àti láti inú ẹ̀yà Benjamini, a fún wọn ní Gibeoni, Geba, Alemeti àti Anatoti lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn. Àwọn ìlú wọ̀nyí, tí a pín láàrín àwọn ẹ̀yà Kohati jẹ́ mẹ́tàlá ní gbogbo rẹ̀.
Y de la tribu de Benjamín: Geba con sus alrededores, y Alemet con sus alrededores, y Anatot con sus alrededores. Todos sus pueblos entre sus familias eran trece pueblos.
61 Ìyókù àwọn ìran ọmọ Kohati ní a pín ìlú mẹ́wàá fún láti àwọn ìdílé ní ti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase.
Y al resto de los hijos de Coat, fueron dados por decisión del Señor diez pueblos de las familias de la tribu de Efraín y de la tribu de Dan y de la media tribu de Manasés.
62 Àwọn ìran ọmọ Gerṣoni, sí ìdílé ni a pín ìlú mẹ́tàlá fún láti ẹ̀yà àwọn ẹ̀yà Isakari, Aṣeri àti Naftali, àti láti apá ẹ̀yà Manase tí ó wà ní Baṣani.
Y a los hijos de Gersón, por sus familias, de la tribu de Isacar, y de la tribu de Aser, y de la tribu de Neftalí, y de la tribu de Manasés en Basán, trece pueblos.
63 Sebuluni àwọn ìran ọmọ Merari, ìdílé sí ìdílé, ní a pín ìlú méjìlá fún láti ẹ̀yà Reubeni, Gadi àti Sebuluni.
Y a los hijos de Merari, por sus familias, doce pueblos fueron dados por decisión del Señor, de la tribu de Rubén, y de la tribu de Gad, y de la tribu de Zabulón.
64 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli fún àwọn ará Lefi ní ìlú wọ̀nyí pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
Y los hijos de Israel dieron a los levitas los pueblos con sus alrededores.
65 Láti ẹ̀yà Juda, Simeoni àti Benjamini ni a pín ìlú tí a ti dárúkọ wọn sẹ́yìn fún.
Y dieron por decisión del Señor la tribu de los hijos de Judá, y la tribu de los hijos de Simeón, y la tribu de los hijos de Benjamín, estos pueblos cuyos nombres reciben.
66 Lára àwọn ìdílé Kohati ni a fún ní ìlú láti ẹ̀yà Efraimu gẹ́gẹ́ bí ìlú agbègbè wọn.
Y a las familias de los hijos de Coat se les dio ciudades por la decisión del Señor de la tribu de Efraín.
67 Ní òkè orílẹ̀-èdè Efraimu, a fún wọn ní Ṣekemu (ìlú ńlá ti ààbò), àti Geseri
Y les dieron la ciudad de refugio, Siquem en la región montañosa de Efraín con sus alrededores, y Gezer con sus alrededores,
68 Jokimeamu, Beti-Horoni.
Y Jocmeam con sus alrededores, y Beth-horon con sus alrededores.
69 Aijaloni àti Gati-Rimoni lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
Y Ajalon con sus alrededores, y Gat-rimón con sus alrededores;
70 Pẹ̀lú láti apá ààbọ̀ ẹ̀yà Manase àwọn ọmọ Israẹli fún Aneri àti Bileamu lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn, fún ìyókù àwọn ìdílé Kohati.
Y de la media tribu de Manasés, Aner con sus alrededores, y Bileam con sus alrededores, para el resto de la familia de los hijos de Coat.
71 Àwọn ará Gerṣoni gbà nǹkan wọ̀nyí. Láti ààbọ̀ ẹ̀yà ti Manase wọ́n gba Golani ní Baṣani àti pẹ̀lú Aṣtarotu, lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù wọn.
Se dieron a los hijos de Gersón, de la familia de la media tribu de Manasés, Golán en Basán con sus alrededores, y Astarot con sus alrededores;
72 Láti ẹ̀yà Isakari wọ́n gba Kedeṣi, Daberati
Y de la tribu de Isacar, Cedes con sus alrededores, y Daberat con sus alrededores,
73 Ramoti àti Anenu, lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
Y Ramot con sus alrededores, y Anem con sus alrededores;
74 Láti ẹ̀yà Aṣeri wọ́n gba Maṣali, Abdoni,
Y de la tribu de Aser, Masal con sus alrededores, y Abdón, Hucoc y Rehob, cada una con sus alrededores.
75 Hukoki àti Rehobu lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
Y Hukok con sus alrededores, y Rehob con sus alrededores;
76 Pẹ̀lú láti ẹ̀yà Naftali wọ́n gba Kedeṣi ní Galili, Hammoni àti Kiriataimu, lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
Y de la tribu de Neftalí, Kedesh en Galilea con sus alrededores, y Hammon con sus alrededores, y Kiriathaim con sus alrededores.
77 Àwọn ará Merari (ìyókù àwọn ará Lefi) gbà nǹkan wọ̀nyí. Láti ẹ̀yà Sebuluni wọ́n gba Jokneamu, Karta, Rimoni àti Tabori, lápapọ̀ pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.
Al resto de los levitas, los hijos de Merari, se les dio de la tribu de Zebulun, Rimmono con sus alrededores, Tabor con sus alrededores;
78 Láti ẹ̀yà Reubeni rékọjá Jordani ìlà-oòrùn Jeriko wọ́n gba Beseri nínú aginjù Jahisa,
Y al otro lado del Jordán, en Jericó, en el lado este del Jordán, se les dio de la tribu de Rubén, Bezer en las tierras baldías con sus alrededores, y Jahzah con sus alrededores,
79 Kedemoti àti Mefaati, lápapọ̀ pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.
Y Cademot con sus alrededores, y Mefaat con sus alrededores;
80 Pẹ̀lú láti ẹ̀yà Gadi wọ́n gba Ramoti ní Gileadi Mahanaimu,
Y de la tribu de Gad, Ramot en Galaad con sus alrededores, y Mahanaim con sus alrededores,
81 Heṣboni àti Jaseri lápapọ̀ pẹ̀lú àwọn ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.
Y Hesbón con sus alrededores, y Hazar con sus alrededores.

< 1 Chronicles 6 >