< 1 Chronicles 5 >
1 Ǹjẹ́ àwọn ọmọ Reubeni, àkọ́bí Israẹli. (Nítorí òun ni àkọ́bí; ṣùgbọ́n, bí ó ti ṣe pé ó ba ibùsùn baba rẹ̀ jẹ́, a fi ogún ìbí rẹ̀ fún àwọn ọmọ Josẹfu ọmọ Israẹli: a kì yóò sì ka ìtàn ìdílé náà gẹ́gẹ́ bí ipò ìbí.
Israilning tunji oƣli Rubǝnning oƣulliri munular: — (Rubǝn gǝrqǝ tunji oƣul bolƣini bilǝn, lekin [atisining toⱪili bilǝn] zina ⱪilƣanliⱪi üqün, uning qong oƣulluⱪ ⱨoⱪuⱪi Israilning oƣli bolƣan Yüsüpning oƣulliriƣa ɵtküzüwetilgǝn. Xunga nǝsǝbnamǝ boyiqǝ u qong oƣul ⱨesablanmaydu.
2 Nítorí Juda borí àwọn arákùnrin rẹ̀, àti lọ́dọ̀ rẹ̀ ni aláṣẹ ti ń jáde wá; ṣùgbọ́n ogún ìbí jẹ́ ti Josẹfu),
Yǝⱨuda ⱪerindaxliri iqidǝ üstünlükkǝ igǝ bolƣan bolsimu wǝ idarǝ ⱪilƣuqi uningdin qiⱪⱪan bolsimu, lekin qong oƣulluⱪ ⱨoⱪuⱪi Yüsüpkǝ tǝwǝ bolup kǝtkǝn): —
3 àwọn ọmọ Reubeni àkọ́bí Israẹli ni: Hanoku àti Pallu, Hesroni àti Karmi.
Israilning tunjisi Rubǝnning oƣulliri munular: — Ⱨanoh wǝ Pallu, Ⱨǝzron wǝ Karmi.
4 Àwọn ọmọ Joẹli: Ṣemaiah ọmọ rẹ̀, Gogu ọmọ rẹ̀, Ṣimei ọmọ rẹ̀.
Yoelning ǝwladliri munular: — [Yoelning] oƣli Xemaya, Xemayaning oƣli Gog, Gogning oƣli Ximǝy,
5 Mika ọmọ rẹ̀, Reaiah ọmọ rẹ̀, Baali ọmọ rẹ̀.
Ximǝyning oƣli Mikaⱨ, Mikaⱨning oƣli Reaya, Reayaning oƣli Baal,
6 Beera ọmọ rẹ̀, tí Tiglat-Pileseri ọba Asiria kó ní ìgbèkùn lọ. Ìjòyè àwọn ọmọ Reubeni ni Beera jẹ́.
Baalning oƣli Bǝǝraⱨ; Bǝǝraⱨ Asuriyǝ padixaⱨi Tilgat-Pilnǝsǝr tǝripidin tutⱪun ⱪilip ketilgǝn. U qaƣda u Rubǝn ⱪǝbilisining baxliⱪi idi.
7 Àti àwọn arákùnrin rẹ̀ nípa ìdílé wọn, nígbà tí a ń ka ìtàn ìdílé ìran wọn: Jeieli àti Sekariah ni olórí,
Uning iniliri nǝsǝbnamisidǝ hatirilǝngǝndǝk, jǝmǝtlirining tarihi boyiqǝ yolbaxqi bolƣan Jǝiyǝl, Zǝkǝriya wǝ Bela dǝp pütülgǝnidi
8 àti Bela ọmọ Asasi ọmọ Ṣema, ọmọ Joẹli. Wọ́n tí ń gbé Aroeri àní títí dé Nebo àti Baali-Meoni.
(Bela Azazning oƣli, Azaz Xemaning oƣli, Xema Yoelning oƣli idi). Yoellar Aroǝrdǝ, Nebo wǝ Baal-Meonƣiqǝ sozulƣan jaylarda turatti.
9 Àti níhà àríwá, o tẹ̀dó lọ títí dé àtiwọ aginjù láti odò Eufurate; nítorí tí ẹran ọ̀sìn wọn pọ̀ sí i ní ilẹ̀ Gileadi.
Ular yǝnǝ kün qiⱪixⱪa ⱪarap taki Əfrat dǝryasining bu tǝripidiki qɵlning kirix eƣiziƣa ⱪǝdǝr olturaⱪlaxti; qünki ularning Gilead yurtidiki qarwa malliri kɵpiyip kǝtkǝnidi.
10 Àti ní ọjọ́ Saulu, wọ́n bá àwọn ọmọ Hagari jagun, ẹni tí ó ṣubú nípa ọwọ́ wọn; wọ́n sì ń gbé inú àgọ́ wọn ní gbogbo ilẹ̀ àríwá Gileadi.
Saulning sǝltǝnitining künliridǝ ular Ⱨagariylar bilǝn urux ⱪilixti; Ⱨagariylar ularning ⱪolida mǝƣlup bolƣandin keyin ular Gileadning kün qiⱪix tǝripidiki pütün zeminda Ⱨagariylarning qedirlirida makanlaxti.
11 Àti àwọn ọmọ Gadi ń gbé lékè wọn, ní ilẹ̀ Baṣani títí dé Saleka:
Ularning udulida Gadning ǝwladliri taki Salikaⱨƣa ⱪǝdǝr Baxan zeminiƣa makanlaxⱪanidi.
12 Joẹli jẹ́ olórí, Ṣafamu ìran ọmọ Janai, àti Ṣafati ni Baṣani.
Baxanda makanlaxⱪanlardin ⱪǝbilǝ baxliⱪi Yoel, muawin ⱪǝbilǝ baxliⱪi Xafam bar idi; yǝnǝ Yanay bilǝn Xafatmu bar idi.
13 Àti àwọn arákùnrin wọn ti ilẹ̀ àwọn baba wọn ní: Mikaeli, Meṣullamu Ṣeba, Jorai, Jaka, Sia àti Eberi méje.
Ularning uruⱪ-tuƣⱪanliri jǝmǝtnamilǝr boyiqǝ Mikail, Mǝxullam, Xeba, Yoray, Yakan, Ziya wǝ Ebǝr bolup, jǝmiy yǝttǝ idi.
14 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Abihaili, ọmọ Huri, ọmọ Jeroa, ọmọ Gileadi, ọmọ Mikaeli, ọmọ Jeṣiṣai, ọmọ Jado, ọmọ Busi.
Yuⱪiridikilǝrning ⱨǝmmisi Abiⱨayilning oƣulliri idi. Abiⱨayil Hurining oƣli, Huri Yaroyaⱨning oƣli, Yaroyaⱨ Gileadning oƣli, Gilead Mikailning oƣli, Mikail Yǝxixayning oƣli, Yǝxixay Yaⱨdoning oƣli, Yaⱨdo buzning oƣli idi;
15 Ahi, ọmọ Adbeeli, ọmọ Guni, olórí ilé àwọn baba wọn.
Gunining nǝwrisi, Abdiǝlning oƣli Ahi ularning jǝmǝt bexi idi.
16 Wọ́n sì ń gbé Gileadi ní Baṣani àti nínú àwọn ìlú rẹ̀, àti nínú gbogbo ìgbèríko Ṣaroni, ní agbègbè wọn.
Ular Gileadⱪa, Baxanƣa wǝ Baxanƣa tǝwǝ yeza-kǝntlǝrgǝ, xundaⱪla pütkül Xaron yayliⱪiƣa, taki tɵt qetigiqǝ makanlaxⱪanidi.
17 Gbogbo wọ̀nyí ni a kà nípa ìtàn ìdílé, ní ọjọ́ Jotamu ọba Juda, àti ní ọjọ́ Jeroboamu ọba Israẹli.
Bularning ⱨǝmmisi Yǝⱨuda padixaⱨi Yotam wǝ Israil padixaⱨi Yǝroboamning sǝltǝnitining künliridǝ nǝsǝbnamilǝrgǝ pütülgǝnidi.
18 Àwọn ọmọ Reubeni, àti àwọn ọmọ Gadi, àti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase, nínú àwọn ọkùnrin alágbára tí wọ́n ń gbé asà àti idà, tí wọ́n sì ń fi ọrun tafà, tí wọ́n sì mòye ogun, jẹ́ ọ̀kẹ́ méjì ó lé ẹgbẹ̀rìnlélógún dín ogójì ènìyàn, tí ó jáde lọ sí ogún náà.
Rubǝn, Gad ⱪǝbililirining wǝ Manassǝⱨ yerim ⱪǝbilisining batur, ⱪalⱪan-ⱪiliq tutalaydiƣan, oⱪya atalaydiƣan ⱨǝm jǝnggǝ maⱨir ⱪiriⱪ tɵt ming yǝttǝ yüz atmix jǝnggiwar adimi bar idi.
19 Wọ́n sì bá àwọn ọmọ Hagari jagun, pẹ̀lú Jeturi, àti Nafiṣi àti Nadabu.
Ular Ⱨagariylar, Yǝturlar, Nafixlar wǝ Nodablar bilǝn jǝng ⱪilƣan.
20 Nígbà tí wọ́n sì rí ìrànlọ́wọ́ gbà si, a sì fi àwọn ọmọ Hagari lé wọn lọ́wọ́, àti gbogbo àwọn tí ó wà pẹ̀lú wọn; nítorí tiwọn ké pe Ọlọ́run ní ogun náà, òun sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ wọn; nítorí tí wọ́n gbẹ́kẹ̀ wọn lé e.
Ular jǝng ⱪilƣanda mǝdǝt tepip, Ⱨagariylar wǝ ular bilǝn ittipaⱪdaxlarning ⱨǝmmisi ularning ⱪoliƣa tapxurulƣan; qünki ular jǝng üstidǝ Hudaƣa nida ⱪilƣan; ular Uningƣa tayanƣaqⱪa, Huda ularning tiligini ijabǝt ⱪilƣan.
21 Wọ́n sì kó ẹran ọ̀sìn wọn lọ; ìbákasẹ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n àti àgùntàn ọ̀kẹ́ méjìlá ó lé ẹgbàárùn-ún, àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì, àti ènìyàn ọ̀kẹ́ márùn-ún.
Ular yǝnǝ düxmǝnning qarwa-mallirini, jümlidin ǝllik ming tɵgǝ, ikki yüz ǝllik ming ⱪoy, ikki ming exikini olja alƣan wǝ yüz ming janni ǝsir alƣan.
22 Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó ṣubú tí a pa, nítorí láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ni ogun náà, wọ́n sì jókòó ní ipò wọn títí di ìgbà ìkólọ sí ìgbèkùn.
Bu urux Hudaning niyitidin bolƣaqⱪa, düxmǝndin ɵlgǝnlǝr naⱨayiti kɵp bolƣan; sürgün ⱪilinƣuqǝ ular xularning yerini ixƣal ⱪilip turƣan.
23 Àwọn ọmọkùnrin ààbọ̀ ẹ̀yà Manase ń gbé ní ilẹ̀ náà: wọ́n bí sí i láti Baṣani títí dé Baali-Hermoni, àti Seniri àti títí dé òkè Hermoni.
Manassǝⱨning yerim ⱪǝbilisidikilǝr Baxandin Baal-ⱨǝrmon, Senir, Ⱨǝrmon teƣiƣa ⱪǝdǝr bolƣan zeminda yeyilip makanlaxti. Ular zor kɵpǝygǝn.
24 Wọ̀nyí sì ni àwọn olórí ilé àwọn baba wọn. Eferi, Iṣi, Elieli, Asrieli, Jeremiah, Hodafiah àti Jahdieli àwọn alágbára akọni ọkùnrin, ọkùnrin olókìkí, àti olórí ilé àwọn baba wọn.
Ularning jǝmǝt baxliⱪliri Efǝr, Ixi, Əliyǝl, Azriǝl, Yǝrimiya, Hodawiya wǝ Yaⱨdiyǝl idi; ularning ⱨǝmmisi naⱨayiti batur jǝngqilǝr, mǝxⱨur mɵtiwǝrlǝr, xundaⱪla ⱨǝrⱪaysisi ɵz jǝmǝtigǝ jǝmǝt bexi idi.
25 Wọ́n sì ṣẹ̀ sí Ọlọ́run àwọn baba wọn, wọ́n sì ṣe àgbèrè tọ àwọn ọlọ́run ènìyàn ilẹ̀ náà lẹ́yìn, tí Ọlọ́run ti parun ní iwájú wọn.
Ular ata-bowilirining Hudasidin yüz ɵrüp, buzuⱪluⱪ ⱪilip Huda ǝslidǝ ɵzliri aldida yoⱪatⱪan xu yǝrdiki taipilǝrning ilaⱨliriƣa ǝgixip kǝtti.
26 Nítorí náà Ọlọ́run Israẹli ru ẹ̀mí Pulu ọba Asiria sókè (èyí ni Tiglat-Pileseri ọba Asiria), ó si kó wọn lọ, àní àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, àti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase lọ sí ìgbèkùn. Ó sì kó wọn wá sí Hala, àti Habori, àti Harani, àti sí etí odò Gosani; títí dí òní yìí.
Xuning bilǝn Israilning Hudasi Asuriyǝ padixaⱨi Pul (yǝni Asuriyǝ padixaⱨi Tilgat-Pilnǝsǝr)ning roⱨini ⱪozƣixi bilǝn, u ularni, yǝni Rubǝn ⱪǝbilisidikilǝrni, Gad ⱪǝbilisidikilǝrni wǝ Manassǝⱨ yerim ⱪǝbilisidikilǝrni Halaⱨ, Habor wǝ Haraƣa ⱨǝm Gozan dǝryasi boyiƣa sürgün ⱪilip elip kǝtti; ularning ǝwladliri taki bügüngǝ ⱪǝdǝr tehiqǝ xu yǝrdǝ makanlixip turmaⱪta.