< 1 Chronicles 3 >

1 Àwọn wọ̀nyí sì ni ọmọ Dafidi tí a bí fún un ní Hebroni. Àkọ́bí sì ni Amnoni ọmọ Ahinoamu ti Jesreeli; èkejì sì ni Daniẹli ọmọ Abigaili ará Karmeli;
E Estes foram os filhos de David, que lhe nasceram em Hebron: o primogênito, Amnon, de Ahinoam, a jizreelita; o segundo, Daniel, de Abigail, a carmelita;
2 ẹ̀kẹta sì ni Absalomu ọmọ Maaka ọmọbìnrin Talmai ọba Geṣuri bí fún un; ẹ̀kẹrin sì ni Adonijah ọmọ Haggiti;
O terceiro, Absalão, filho de Maaca, filha de Talmai, rei de Gesur; o quarto, Adonias, filho de Haggith;
3 ẹ̀karùnún ni Ṣefatia láti ọ̀dọ̀ Abitali; àti ẹ̀kẹfà, Itreamu, láti ọ̀dọ̀ Egla aya rẹ̀.
O quinto, Sephatias, de Abital; o sexto, Ithream, de Egla, sua mulher.
4 Àwọn mẹ́fà wọ̀nyí ni a bí fún Dafidi ni Hebroni, níbi tí ó ti jẹ ọba fún ọdún méje àti oṣù mẹ́fà. Dafidi sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n.
Seis lhe nasceram em Hebron, porque ali reinou sete anos e seis meses: e trinta e três anos reinou em Jerusalém.
5 Wọ̀nyí ni ọmọ wẹ́wẹ́ tí a bí fún un ní Jerusalẹmu: Ṣimea, Ṣobabu, Natani àti Solomoni. Àwọn mẹ́rin wọ̀nyí sì ni a bí láti ọ̀dọ̀ Bati-Ṣua ọmọbìnrin Ammieli.
E estes lhe nasceram em Jerusalém: Simea, e Sobab, e Nathan, e Salomão: estes quatro lhe nasceram de Bath-sua, filha de Ammiel.
6 Ibhari sì wà pẹ̀lú, Eliṣama, Elifeleti,
Nasceram-lhe mais Ibehar, e Elisama, e Eliphelet,
7 Noga, Nefegi, Jafia,
E Nogath, e Nepheg, e Japhia,
8 Eliṣama, Eliada àti Elifeleti mẹ́sàn-án ni wọ́n.
E Elisama, e Eliad, e Eliphelet, nove.
9 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Dafidi yàtọ̀ sí àwọn ọmọ tí àlè bí fún un. Tamari sì ni arábìnrin wọn.
Todos estes foram filhos de David, a fora os filhos das concubinas, e Tamar, irmã deles.
10 Ọmọ Solomoni ni Rehoboamu, Abijah ọmọ rẹ̀, Asa ọmọ rẹ̀, Jehoṣafati ọmọ rẹ̀,
E filho de Salomão foi Roboão; e seu filho Abias; e seu filho Asa; e seu filho Josaphat;
11 Jehoramu ọmọ rẹ̀, Ahasiah ọmọ rẹ̀, Joaṣi ọmọ rẹ̀,
E seu filho Jorão; e seu filho Achazias; e seu filho Joás;
12 Amasiah ọmọ rẹ̀, Asariah ọmọ rẹ̀, Jotamu ọmọ rẹ̀,
E seu filho Amasias; e seu filho Jotham;
13 Ahasi ọmọ rẹ̀, Hesekiah ọmọ rẹ̀, Manase ọmọ rẹ̀,
E seu filho Achaz; e seu filho Ezequias; e seu filho Manassés;
14 Amoni ọmọ rẹ̀, Josiah ọmọ rẹ̀.
E seu filho Amon; e seu filho Josias.
15 Àwọn ọmọ Josiah: àkọ́bí ọmọ rẹ̀ ni Johanani, èkejì ọmọ rẹ̀ ni Jehoiakimu, ẹ̀kẹta ọmọ rẹ̀ ni Sedekiah, ẹ̀kẹrin ọmọ rẹ̀ ni Ṣallumu.
E os filhos de Josias foram: o primogênito, Johanan; o segundo, Joaquim; o terceiro, Zedekias; o quarto, Sallum.
16 Àwọn ìran ọmọ Jehoiakimu: Jekoniah ọmọ rẹ̀, àti Sedekiah.
E os filhos de Joaquim: Jechonias, seu filho, e Zedekias, seu filho.
17 Àwọn ọmọ Jekoniah tí a mú ní ìgbèkùn: Ṣealitieli ọmọ rẹ̀ ọkùnrin,
E os filhos de Jechonias: Assir, e seu filho Sealthiel.
18 Malkiramu, Pedaiah, Ṣenasari, Jekamiah, Hoṣama àti Nedabiah.
Os filhos deste foram: Malchiram, e Pedaia, e Senazzar, Jekamias, Hosama, e Nedabias.
19 Àwọn ọmọ Pedaiah: Serubbabeli àti Ṣimei. Àwọn ọmọ Serubbabeli: Meṣullamu àti Hananiah. Ṣelomiti ni arábìnrin wọn.
E os filhos de Pedaia: Zorobabel e Simei; e os filhos de Zorobabel: Messullam, e Hananias, e Selomith, sua irmã,
20 Àwọn márùn-ún mìíràn sì tún wà: Haṣuba, Oheli, Berekiah, Hasadiah àti Jusabhesedi.
E Hasuba, e Obel, e Berechias, e Hasadias, e Jusab-hesed, cinco.
21 Àwọn ọmọ Hananiah: Pelatiah àti Jeṣaiah, àti àwọn ọmọ Refaiah, ti Arnani, ti Obadiah àti ti Ṣekaniah.
E os filhos de Hananias: Pelatias e Jesaias: os filhos de Rephaias, os filhos d'Arnan, os filhos de Obadias, e os filhos de Secanias.
22 Àwọn ọmọ Ṣekaniah: Ṣemaiah àti àwọn ọmọ rẹ̀: Hattusi, Igali, Bariah, Neariah àti Ṣafati, mẹ́fà ni gbogbo wọn.
E os filhos de Secanias foram Semaias: e os filhos de Semaias: Hattus, e Igeal, e Bariah, e Nearias, e Saphat, seis.
23 Àwọn ọmọ Neariah: Elioenai; Hesekiah, àti Asrikamu, mẹ́ta ni gbogbo wọn.
E os filhos de Nearias: Elioenai, e Ezequias, e Azrikam, três.
24 Àwọn ọmọ Elioenai: Hodafiah, Eliaṣibu, Pelaiah, Akkubu, Johanani, Delaiah àti Anani, méje sì ni gbogbo wọn.
E os filhos de Elioenai: Hodavias, e Eliasib, e Pelaias, e Akkub, e Johanan, e Delaias, e Anani, sete.

< 1 Chronicles 3 >