< 1 Chronicles 29 >

1 Nígbà náà, ọba Dafidi sọ fún gbogbo àpéjọ pé, “Ọmọ mi Solomoni, èyí tí Ọlọ́run ti yàn, sì kéré ó sì jẹ́ aláìmòye. Iṣẹ́ náà tóbi, nítorí ìkọ́lé bí ti ààfin kì í ṣe fún ènìyàn ṣùgbọ́n fún Olúwa Ọlọ́run.
Ningĩ Mũthamaki Daudi akĩĩra kĩũngano kĩu gĩothe atĩrĩ: “Mũriũ wakwa Solomoni, ũrĩa Ngai athuurĩte, nĩ mwĩthĩ na ndarĩ na ũmenyo wa kũigana. Wĩra ũyũ nĩ mũnene, tondũ nyũmba ĩno ĩhaana ta ya ũthamaki ti ya mũndũ no nĩ ya Jehova Ngai.
2 Pẹ̀lú gbogbo ìrànlọ́wọ́ mi èmi ti pèsè fún ilé Ọlọ́run mi wúrà fún iṣẹ́ wúrà, fàdákà fún ti fàdákà, idẹ fún ti idẹ, irin fún ti irin àti igi fún ti igi àti òkúta oníyebíye fún títọ́ rẹ̀, òkúta lóríṣìíríṣìí, àwọ̀ àti oríṣìíríṣìí ẹ̀yà òkúta àti òkúta dáradára kan gbogbo wọ̀nyí ní iye púpọ̀.
Nĩnjigithĩtie indo na ũhoti wakwa wothe nĩ ũndũ wa hekarũ ya Ngai wakwa, ngaiga thahabu nĩ ũndũ wa gũthondeka indo cia thahabu, na betha nĩ ũndũ wa gũthondeka indo cia betha, na gĩcango nĩ ũndũ wa gũthondeka indo cia gĩcango, na kĩgera nĩ ũndũ wa gũthondeka indo cia kĩgera, na mbaũ nĩ ũndũ wa gũthondeka indo cia mbaũ, o na tũhiga tũrĩa twĩtagwo onigithi tũrĩa tũtheecagĩrĩrwo indo-inĩ, na tũhiga tũrĩa tũhenagia twa kũgemia nyũmba, na tũhiga twa rangi wa mĩthemba mĩingĩ, na tũhiga twa goro twa mĩthemba mĩingĩ, na mahiga ma nyaigĩ ma mũthemba ũrĩa mwega, indo icio ciothe ngaigithia irĩ nyingĩ mũno.
3 Yàtọ̀ fún èyí, nínú ìfọkànsìn mi sí ilé Ọlọ́run mi, èmí fi ìṣúra mi tìkára mi ti wúrà àti fàdákà fún ilé Ọlọ́run mi. Jù gbogbo rẹ̀ lọ, èmi ti pèsè fún ilé mímọ́ ti Olúwa yìí,
Makĩria ma ũguo, harĩ kwĩrutĩra gwakwa igũrũ rĩa hekarũ ya Ngai wakwa nĩngũheana kĩgĩĩna gĩakwa mwene gĩa thahabu na betha nĩ ũndũ wa hekarũ ya Ngai wakwa, na icio ngũciheana nyongerere kĩrĩa kĩngĩ njigithĩtie nĩ ũndũ wa hekarũ ĩno theru:
4 ẹgbẹ̀rún mẹ́ta tálẹ́ǹtì wúrà, ti wúrà Ofiri àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin tálẹ́ǹtì fàdákà dídára, fún bíbo àwọn ògiri ilé náà.
ngũheana taranda ngiri ithatũ cia thahabu, o thahabu ĩrĩa ya Ofiri, na taranda ngiri mũgwanja cia betha ĩrĩa therie nĩ ũndũ wa kũgemia thingo cia nyũmba,
5 Fún iṣẹ́ wúrà àti fàdákà náà, àti fún oríṣìí iṣẹ́ ti ó yẹ ní ṣíṣe nípasẹ̀ àwọn tí ó ní òye oríṣìíríṣìí iṣẹ́. Nísinsin yìí, ta ni ó ní ìfẹ́ sí yíya ará rẹ̀ sọ́tọ̀ lónìí sí Olúwa?”
o na nĩ ũndũ wa wĩra wa thahabu na indo cia wĩra wa betha ũrĩa wothe ũkaarutwo nĩ mabundi. Na rĩrĩ, nũũ ũkwĩĩamũrĩra Jehova ũmũthĩ na kwĩyendera?”
6 Nígbà náà àwọn aṣáájú àwọn ìdílé, àwọn ìjòyè àwọn ẹ̀yà Israẹli, àwọn alákòóso ẹgbẹgbẹ̀wàá àti alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún àti àwọn oníṣẹ́ tí ó wà ní ìdí iṣẹ́ ọba ní ìfẹ́ sí i.
Hĩndĩ ĩyo atongoria a nyũmba, na anene a mĩhĩrĩga ya Isiraeli, na anene a ikundi cia ngiri ngiri na anene a ikundi cia igana igana na anene arĩa maarũgamagĩrĩra wĩra wa mũthamaki makĩheana indo na kwĩyendera.
7 Wọ́n fi sílẹ̀ fún iṣẹ́ lórí ilé Ọlọ́run, ẹgbẹ̀rún márùn-ún tálẹ́ǹtì àti ẹgbẹ̀rin mẹ́wàá wúrà, ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá tálẹ́ǹtì fàdákà, ẹgbàá mẹ́sàn tálẹ́ǹtì idẹ àti ọgọ́rin ẹgbẹ̀rin tálẹ́ǹtì irin.
Nĩ ũndũ wa wĩra wa hekarũ ya Ngai nĩmaheanire taranda ngiri ithano, na dariki ngiri ikũmi cia thahabu, na taranda ngiri ikũmi cia betha, na taranda ngiri ikũmi na inyanya cia gĩcango, na taranda ngiri igana rĩmwe cia kĩgera.
8 Ẹnikẹ́ni tí ó ní òkúta iyebíye fi wọn sí ilé ìṣúra ilé Olúwa ní abẹ́ ìtọ́jú Jehieli ará Gerṣoni.
Mũndũ o wothe warĩ na tũhiga twa goro nĩatũheanire thĩinĩ wa kĩgĩĩna kĩa hekarũ ya Jehova kĩrĩa kĩamenyagĩrĩrwo nĩ Jehieli ũrĩa Mũgerishoni.
9 Àwọn ènìyàn láyọ̀ nínú ìṣesí àtọkànwá fi sílẹ̀ àwọn olórí wọn, nítorí tí wọ́n ti fi sílẹ̀ ní ọ̀fẹ́ pẹ̀lú gbogbo ọkàn sí Olúwa. Dafidi ọba pẹ̀lú yọ̀ gidigidi.
Andũ nĩmakenirio nĩ ũrĩa atongoria ao maamũkĩire ũhoro ũcio na kwĩyendera, tondũ nĩmarutĩire Jehova indo na ngoro yao yothe matekũringĩrĩrio. Mũthamaki Daudi o nake nĩakenire mũno.
10 Dafidi yin Olúwa níwájú gbogbo àwọn tí ó péjọ, wí pé, “Ìyìn ni fún Ọ, Olúwa, Ọlọ́run baba a wa Israẹli, láé àti láéláé.
Daudi nĩagoocire Jehova arĩ mbere ya kĩũngano kĩu gĩothe, akiuga atĩrĩ, “Ũrogoocwo wee, o Wee Jehova, Ngai wa ithe witũ Isiraeli, kuuma tene nginya tene.
11 Tìrẹ Olúwa ni títóbi àti agbára pẹ̀lú ìyìn àti ọláńlá àti dídán, nítorí tí gbogbo nǹkan ní ọ̀run àti ayé jẹ́ tìrẹ. Tìrẹ Olúwa ni ìjọba; a gbé ọ ga gẹ́gẹ́ bí orí lórí ohun gbogbo.
Wee Jehova-rĩ, ũnene, na hinya, na riiri, na wathani, na ũkengi nĩ ciaku, nĩgũkorwo kĩndũ o gĩothe kĩrĩ igũrũ na thĩ nĩ gĩaku. Wee Jehova, ũthamaki nĩ waku; nĩũtũũgĩrĩtio, ũkanenehio gũkĩra indo ciothe.
12 Ọlá àti ọ̀wọ̀ wá láti ọ̀dọ̀ Rẹ; ìwọ ni alákòóso gbogbo nǹkan. Ní ọwọ́ rẹ ni ipá àti agbára wà láti gbéga àti láti fi agbára fún ohun gbogbo.
Ũtonga na gĩtĩĩo ciumaga kũrĩ we; Wee nĩwe wathaga indo ciothe. Hinya na ũhoti wa gũtũũgĩria o na kũhe andũ othe hinya irĩ moko-inĩ maku.
13 Nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, àwa fi ọpẹ́ fún Ọ, a sì fi ìyìn fún orúkọ rẹ̀ tí ó lógo.
Na rĩrĩ, Ngai witũ, nĩtũgũgũcookeria ngaatho, na tũkagooca rĩĩtwa rĩaku rĩrĩ riiri.
14 “Ṣùgbọ́n ta ni èmi, àti ta ni àwọn ènìyàn mi, tí a fi lè ṣe ìrànlọ́wọ́ tinútinú bí irú èyí? Gbogbo nǹkan wá láti ọ̀dọ̀ rẹ ní ti wá, àwa sì ti fífún ọ láti ara ohun tí ó wá láti ọwọ́ rẹ.
“No niĩ ngĩrĩ ũ, nao andũ akwa-rĩ, makĩrĩ a, atĩ no tũhote kũheana na ũtaana ta ũyũ? Indo ciothe ciumaga kũrĩ we, na kĩrĩa twakũhe no kĩrĩa kiumĩte moko-inĩ maku.
15 Àwa jẹ́ àjèjì àti àlejò ní ojú rẹ gẹ́gẹ́ bí baba ńlá a wa, àwọn ọjọ́ wa lórí ilẹ̀ ayé rí bí òjìji láìsí ìrètí.
Ithuĩ tũrĩ ageni na agendi maitho-inĩ maku, o ta ũrĩa maithe maitũ ma tene othe maatariĩ. Matukũ maitũ gũkũ thĩ matariĩ o ta kĩĩruru, na gũtirĩ mwĩhoko wa gũtũũra.
16 Olúwa Ọlọ́run wa tí fi gbogbo púpọ̀ yìí tí àwa ti pèsè fún kíkọ́ ilé Olúwa fun orúkọ, mímọ́ rẹ̀, ó wá láti ọwọ́ ọ̀ rẹ, gbogbo rẹ̀ sì jẹ́ tirẹ̀.
Wee Jehova Ngai witũ, ũingĩ wa indo ici twaruta cia gũgwakĩra hekarũ nĩ ũndũ wa Rĩĩtwa rĩaku Itheru ciumĩte guoko-inĩ gwaku, na ciothe no ciaku.
17 Èmi mọ̀ Ọlọ́run mi, wí pé ìwọ̀ dán ọkàn wò, ó sì tẹ́ ọ lọ́rùn pẹ̀lú òtítọ́ inú. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi ti fi sílẹ̀ pẹ̀lú tìfẹ́tìfẹ́ pẹ̀lú òtítọ́. Nísinsin yìí èmi ti rí i pẹ̀lú ayọ̀ bí àwọn ènìyàn yìí tí ó wà níbí ti fi fún ọ pẹ̀lú tìfẹ́tìfẹ́.
Niĩ nĩnjũũĩ atĩ Wee Ngai wakwa nĩũtuĩragia ngoro, na nĩũkenagio nĩ ũrũngĩrĩru wa ngoro. Indo ici ciothe ndĩciheanĩte na kwĩyendera na wĩhokeku. Na rĩu ndĩ na gĩkeno nĩ ũndũ wa kwĩonera ũrĩa andũ aya aku marĩ haha makũrutĩire indo na wendo.
18 Olúwa Ọlọ́run àwọn baba a wa Abrahamu, Isaaki àti Israẹli pa ìfẹ́ yìí mọ́ nínú ọkàn àwọn ènìyàn rẹ títí láé pẹ̀lú pípa ọkàn mọ́ lóòtítọ́ sí ọ.
Wee Jehova, Ngai wa maithe maitũ Iburahĩmu, na Isaaka na Isiraeli, tũũria wendo ũyũ ũrĩ ngoro-inĩ cia andũ aku nginya tene na ũtũme matũũre magwathĩkagĩra.
19 Àti fún ọmọ mi Solomoni ní ìfọkànsìn tòótọ́ láti pa àṣẹ rẹ mọ́ àwọn ohun tí ó nílò àti òfin àti láti ṣe ohun gbogbo láti kọ́ ààfin bí ti ọba fún èyí tí mo ti pèsè.”
Na ũhotithie mũriũ wakwa Solomoni kwĩrutĩra na ngoro yake yothe, kũmenyagĩrĩra maathani maku, na maũndũ marĩa wee wendaga o na kĩrĩra gĩaku kĩa watho wa kũrũmĩrĩrwo, na ekage maũndũ mothe nĩguo aake mwako wa nyũmba ĩno ĩhaana ta nyũmba ya ũthamaki, ĩrĩa niĩ njigithĩirie indo ciayo.”
20 Dafidi sì sọ fún gbogbo ìjọ ènìyàn pé, “Nísinsin yìí, ẹ fi ìyìn fún Olúwa Ọlọ́run yín.” Gbogbo ènìyàn sì fi ìyìn fún Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn, wọ́n sì tẹ orí wọn ba, wọ́n wólẹ̀ fún Olúwa àti ọba.
Ningĩ Daudi akĩĩra kĩũngano gĩothe atĩrĩ, “Goocai Jehova Ngai wanyu.” Nĩ ũndũ ũcio andũ othe makĩgooca Jehova Ngai wa maithe mao; makĩinamĩrĩra, na makĩĩgũithia thĩ mbere ya Jehova na mbere ya mũthamaki.
21 Ni ọjọ́ kejì, wọ́n rú ẹbọ sí Olúwa, wọ́n sì rú ẹbọ sísun sí i: ẹgbẹ̀rún kan akọ màlúù, ẹgbẹ̀rin kan àgbò, àti ẹgbẹ̀rin kan akọ ọ̀dọ́-àgùntàn. Lápapọ̀ pẹ̀lú ọrẹ mímu àti àwọn ẹbọ mìíràn ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ fún gbogbo Israẹli.
Mũthenya ũyũ ũngĩ makĩrutĩra Jehova magongona na makĩmũrutĩra maruta ma njino, ta ũũ: ndegwa ngiri ĩmwe, na ndũrũme ngiri ĩmwe na tũtũrũme ngiri ĩmwe, o hamwe na maruta mao ma indo cia kũnyuuo na magongona mangĩ maingĩ nĩ ũndũ wa andũ a Isiraeli othe.
22 Wọ́n jẹ wọ́n sì mu pẹ̀lú ayọ̀ kíkún ní iwájú Olúwa ní ọjọ́ náà. Nígbà náà wọ́n yan Solomoni ọmọ Dafidi gẹ́gẹ́ bí ọba lẹ́ẹ̀kejì wọ́n fi àmì òróró yàn án níwájú Olúwa láti ṣe olórí àti Sadoku láti ṣe àlùfáà.
Makĩrĩa na makĩnyua marĩ na gĩkeno kĩnene mũthenya ũcio marĩ hau mbere ya Jehova. Ningĩ makĩamũkĩra Solomoni mũrũ wa Daudi arĩ mũthamaki hĩndĩ ya keerĩ, na makĩmũitĩrĩria maguta mbere ya Jehova atuĩke wa kũmathamakĩra, nake Zadoku atuĩke mũthĩnjĩri-Ngai.
23 Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni jókòó lórí ìtẹ́ Olúwa gẹ́gẹ́ bí ọba ní ipò baba a rẹ̀ Dafidi. O ṣe àṣeyọrí, gbogbo Israẹli sì gbọ́rọ̀ sí i lẹ́nu.
Nĩ ũndũ ũcio Solomoni agĩikarĩra gĩtĩ gĩa ũthamaki kĩa Jehova, na agĩtuĩka mũthamaki ithenya rĩa ithe Daudi. Nake akĩgaacĩra na agĩathĩkĩrwo Isiraeli guothe.
24 Gbogbo àwọn ìjòyè àti àwọn ọkùnrin alágbára, pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ ọba Dafidi tẹrí ara wọn ba fún ọba Solomoni.
Anene othe, na andũ arĩa maarĩ njamba, hamwe na ariũ a Mũthamaki Daudi othe magĩtĩkĩra Mũthamaki Solomoni amaathage.
25 Olúwa gbé Solomoni ga púpọ̀ ní ojú gbogbo Israẹli, ó sì kẹ́ ẹ ní ìkẹ́ ọláńlá, ní irú èyí tí a kò kẹ́ ọba kankan ṣáájú rẹ̀ tí ó jẹ lórí Israẹli.
Jehova agĩtũũgĩria Solomoni mũno maitho-inĩ ma andũ a Isiraeli othe, na akĩmũhe ũthamaki ũrĩ na riiri ũtaahetwo mũthamaki ũngĩ wa Isiraeli mbere ĩyo.
26 Dafidi ọmọ Jese jẹ́ ọba lórí gbogbo Israẹli.
Daudi mũrũ wa Jesii aarĩ mũthamaki wa Isiraeli guothe.
27 Ó jẹ ọba lórí Israẹli fún ogójì ọdún; ọdún méje ni ó jẹ ọba ní Hebroni, ó sì jẹ ọba ní ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ní Jerusalẹmu.
Aathamakĩire Isiraeli mĩaka mĩrongo ĩna, mĩaka mũgwanja yayo agĩthamaka arĩ Hebironi, nayo mĩaka mĩrongo ĩtatũ na ĩtatũ agĩthamaka arĩ Jerusalemu.
28 Òun sì darúgbó, ó sì kú ikú rere, ó gbádùn ẹ̀mí gígùn, ọlá àti ọrọ̀. Solomoni ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Aakuire arĩ mũkũrũ mũno, arĩkĩtie gũkenera gũtũũra gwake matukũ maingĩ, na arĩ mũtongu, na agatĩĩo. Mũriũ Solomoni nĩwe wathamakire ithenya rĩake.
29 Ní ti ohun tí ó ṣẹlẹ̀ nígbà ìjọba ọba Dafidi, láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin, a kọ wọ́n sínú ìwé ìrántí ti Samuẹli aríran, ìwé ìrántí ti Natani wòlíì àti ìwé ìrántí ti Gadi aríran,
Naho ha maũndũ marĩa makoniĩ wathani wa Mũthamaki Daudi kuuma kĩambĩrĩria nginya mũthia, nĩmandĩkĩtwo thĩinĩ wa maandĩko ma Samũeli ũrĩa warĩ muoni-maũndũ, na maandĩko-inĩ ma Nathani ũrĩa mũnabii na maandĩko-inĩ ma Gadi ũrĩa muoni-maũndũ,
30 lápapọ̀, pẹ̀lú gbogbo ìjọba àti agbára rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ìgbà tí ó kọjá lórí rẹ̀, àti lórí Israẹli, àti lórí gbogbo àwọn ìjọba gbogbo ilẹ̀ náà.
hamwe na maũndũ mothe marĩa maakoniĩ ũthamaki wake na ũhoti ũrĩa aarĩ naguo, na ũrĩa maũndũ marĩa maamũthiũrũrũkĩirie maatariĩ na ma Isiraeli na mothamaki ma mabũrũri marĩa mangĩ mothe.

< 1 Chronicles 29 >