< 1 Chronicles 25 >
1 Pẹ̀lúpẹ̀lú Dafidi àti àwọn olórí àwọn ọmọ-ogun, ó sì yà díẹ̀ sọ́tọ̀ lára àwọn ọmọ Asafu, Hemani àti Jedutuni fún ìsìn àsọtẹ́lẹ̀, pẹ̀lú dùùrù, ohun èlò orin olókùn àti kimbali. Èyí sì ní àwọn iye àwọn ọkùnrin ẹni tí ó ṣe oníṣẹ́ ìsìn yìí.
Daudi arĩ hamwe na anene a mbũtũ cia ita nĩamũrire ariũ amwe a Asafu, na Hemani, na Jeduthuni marutage wĩra wa ũrathi makĩhũũraga inanda cia mũgeeto, na cia kĩnũbi, na thaani iria ihũũrithanagio ikagamba. Maya nĩmo marĩĩtwa ma andũ arĩa maarutaga wĩra ũyũ wa kũina:
2 Nínú àwọn ọmọ Asafu: Sakkuri, Josẹfu, Netaniah àti Asarela, àwọn ọmọ Asafu ni wọ́n wà lábẹ́ ìbojútó Asafu, ẹni tí ó sọtẹ́lẹ̀ lábẹ́ ìbojútó ọba.
Kuuma kũrĩ ariũ a Asafu: maarĩ Zakuri, na Jusufu, na Nethania, na Asarela. Ariũ a Asafu maarũgamagĩrĩrwo nĩ Asafu, ũrĩa warathaga ũhoro arũgamĩrĩirwo nĩ mũthamaki.
3 Gẹ́gẹ́ bí ti Jedutuni, nínú àwọn ọmọkùnrin rẹ̀: Gedaliah, Seri, Jeṣaiah, Ṣimei, Haṣabiah àti Mattitiah, mẹ́fà nínú gbogbo wọn, lábẹ́ ìbojútó baba wọn Jedutuni, ẹni tí ó sọtẹ́lẹ̀, ẹni tí ó lo dùùrù láti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa.
Kuuma kũrĩ ariũ a Jeduthuni: maarĩ Gedalia, na Zeri, na Jeshaia, na Shimei, na Hashabia, na Matithia; othe maarĩ atandatũ, marũgamĩrĩirwo nĩ ithe wao Jeduthuni, ũrĩa warathaga ũhoro, akĩhũũraga kĩnanda kĩa mũgeeto, agacookagĩria Jehova ngaatho na akamũgoocaga.
4 Gẹ́gẹ́ bí ti Hemani, nínú àwọn ọmọ rẹ̀: Bukkiah, Mattaniah, Usieli, Ṣubaeli àti Jerimoti; Hananiah, Hanani, Eliata, Giddalti, àti Romamtieseri, Joṣbekaṣa, Malloti, Hotiri, Mahasiotu.
Kuuma kũrĩ ariũ a Hemani: maarĩ Bukia, na Matania, na Uzieli, na Shubaeli, na Jerimothu, na Hanania, na Hanani, na Eliatha, na Gidaliti, na Romamuti-Ezeri, na Joshibekasha, na Malothi, na Hothiru, na Mahaziothu.
5 Gbogbo àwọn wọ̀nyí sì ni ọmọ Hemani àti wòlíì ọba. Wọ́n sì fi wọ́n fún nípa ìlérí Ọlọ́run láti máa gbé ìwo sókè. Ọlọ́run sì fún Hemani ní ọmọkùnrin mẹ́rìnlá àti àwọn ọmọbìnrin mẹ́ta.
Acio othe maarĩ ariũ a Hemani ũrĩa wonagĩra mũthamaki maũndũ. Maaheanĩtwo kũrĩ we kũringana na ciĩranĩro cia Ngai nĩguo mamũtũũgagĩrie. Ngai aaheete Hemani ariũ ikũmi na ana, na airĩtu atatũ.
6 Gbogbo àwọn ọkùnrin yìí ni wọ́n wà lábẹ́ ìbojútó àwọn baba wọn fún ohun èlò orin ilé Olúwa, pẹ̀lú kimbali, ohun èlò orin olókùn àti dùùrù, fún ìsìn ilé Olúwa. Asafu, Jedutuni àti Hemani sì wà lábẹ́ ọba.
Andũ aya othe maarũgamagĩrĩrwo nĩ maithe mao nĩguo mainage thĩinĩ wa hekarũ ya Jehova, marĩ na thaani iria ihũũrithanagio ikagamba, na inanda cia kĩnũbi, na inanda cia mũgeeto, nĩ ũndũ wa ũtungata wa nyũmba ya Ngai. Asafu, na Jeduthuni, na Hemani nao maarũgamagĩrĩrwo nĩ mũthamaki.
7 Àwọn ìdílé wọn pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó mòye àti àwọn tí a kọ́ ní ohun èlò orin fún Olúwa, iye wọn sì jẹ́ ọ̀rìnlélúgba ó lé mẹ́jọ.
Hamwe na andũ a nyũmba ciao, arĩa othe maarutĩtwo na makagĩa na ũũgĩ wa kũinĩra Jehova, othe maarĩ andũ 288.
8 Kékeré àti àgbà bákan náà, olùkọ́ àti gẹ́gẹ́ bí ti akẹ́kọ̀ọ́, ṣẹ́ kèké fún iṣẹ́ wọn.
Andũ ethĩ na akũrũ ũndũ ũmwe, na arutani o na arutwo, nĩmacuukire mĩtĩ nĩguo magaĩrwo mawĩra mao.
9 Kèké èkínní èyí tí ó jẹ́ ti Asafu, jáde sí Josẹfu, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá èkejì sì ni Gedaliah, òun àti àwọn ìdílé rẹ̀ àti àwọn ọmọ rẹ̀, méjìlá
Mũtĩ wa mbere, ũrĩa warĩ wa Asafu, wagwĩrĩire Jusufu, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12; wa keerĩ wagwĩrĩire Gedalia, we na andũ a nyũmba yao, na ariũ ao, maarĩ andũ 12;
10 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sí Sakkuri, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé, méjìlá
wa gatatũ wagũĩrĩire Zakuri, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
11 ẹlẹ́ẹ̀kẹrin sí Isiri, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
wa kana wagũĩrĩire Iziri, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
12 ẹlẹ́ẹ̀karùnún sí Netaniah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
wa gatano wagũĩrĩire Nethania, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
13 ẹlẹ́ẹ̀kẹfà sí Bukkiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
wa gatandatũ wagũĩrĩire Bukia, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
14 ẹlẹ́ẹ̀keje sí Jasarela, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
wa mũgwanja wagũĩrĩire Jesarela, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
15 ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ sí Jeṣaiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
wa kanana wagũĩrĩire Jeshaia, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
16 ẹlẹ́ẹ̀kẹsàn-án sí Mattaniah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
wa kenda wagũĩrĩire Matania, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
17 ẹlẹ́ẹ̀kẹwàá sí Ṣimei, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
wa ikũmi wagũĩrĩire Shemei, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
18 ẹlẹ́ẹ̀kọkànlá sí Asareeli, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa ikũmi na ũmwe wagũĩrĩire Azareli, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
19 ẹlẹ́ẹ̀kẹjìlá sí Haṣabiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa ikũmi na ĩĩrĩ wagũĩrĩire Hashabia, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
20 ẹlẹ́ẹ̀kẹtàlá sí Ṣubaeli, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa ikũmi na ĩtatũ wagũĩrĩire Shubaeli, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
21 ẹlẹ́ẹ̀kẹrìnlá sí Mattitiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa ikũmi na ĩna wagũĩrĩire Matithia, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
22 ẹlẹ́ẹ̀kẹẹ̀dógún sí Jerimoti, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa ikũmi na ĩtano wagũĩrĩire Jerimothu, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
23 ẹlẹ́ẹ̀kẹrìndínlógún sí Hananiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa ikũmi na ĩtandatũ wagũĩrĩire Hanania, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
24 ẹlẹ́ẹ̀kẹtàdínlógún sí Joṣbekaṣa, àwọn ọmọ rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa ikũmi na mũgwanja wagũĩrĩire Joshibekasha, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
25 ẹlẹ́ẹ̀kejìdínlógún sí Hanani, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa ikũmi na ĩnana wagũĩrĩire Hanani, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
26 ẹlẹ́ẹ̀kọkàndínlógún sí Malloti, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa ikũmi na kenda wagũĩrĩire Malothi, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
27 ogún sí Eliata, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa mĩrongo ĩĩrĩ wagũĩrĩire Eliatha, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
28 ẹlẹ́ẹ̀kọkànlélógún sí Hotiri, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa mĩrongo ĩĩrĩ na ũmwe wagũĩrĩire Hothiru, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
29 ẹlẹ́ẹ̀kejìlélógún sí Giddalti, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa mĩrongo ĩĩrĩ na ĩĩrĩ wagũĩrĩire Gidaliti, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
30 ẹlẹ́ẹ̀kẹtàlélógún sí Mahasiotu, àwọn ọmọ rẹ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
wa mĩrongo ĩĩrĩ na ĩtatũ wagũĩrĩire Mahaziothu, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12;
31 ẹlẹ́ẹ̀kẹrìnlélógún sí Romamtieseri àwọn ọmọ rẹ̀, àti àwọn ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá.
wa mĩrongo ĩĩrĩ na ĩna wagũĩrĩire Romamuti-Ezeri, na ariũ ake, na andũ a nyũmba yao, maarĩ andũ 12.