< 1 Chronicles 24 >

1 Àwọn wọ̀nyí sì ni pínpín àwọn ọmọ Aaroni. Àwọn ọmọ Aaroni ni Nadabu, Abihu, Eleasari àti Itamari.
و اين است فرقه هاي بني هارون: پسران هارون، ناداب و اَبِيهُو و اَلِعازار و ايتامار.۱
2 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú kí ó tó di wí pé baba wọn kú, wọn kò sì ní àwọn ọmọ; bẹ́ẹ̀ ni Eleasari àti Itamari sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àlùfáà.
و ناداب و اَبِيهُو قبل از پدر خود مُردند و پسري نداشتند، پس اَلِعازار و ايتامار به کهانت پرداختند.۲
3 Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Sadoku ọmọ Eleasari àti Ahimeleki ọmọ Itamari, Dafidi sì yà wọ́n nípa nínú ìpín fún ìyàsọ́tọ̀ àwọn iṣẹ́ ìsìn wọn.
و داود با صادوق که از بني اَلِعازار بود و اَخِيمَلَک که از بني ايتامار بود،۳
4 A rí ọ̀pọ̀ àwọn olórí lára àwọn ọmọ Eleasari ju lára àwọn ọmọ Itamari lọ, wọ́n sì pín wọn lẹ́sẹ lẹ́sẹ: mẹ́rìndínlógún olórí láti ìdílé ọmọ Eleasari ìran wọn àti olórí méjọ ìdílé láti ara àwọn ọmọ Itamari.
و از پسران اَلِعازار مرداني که قابل رياست بودند، زياده از بني ايتامار يافت شدند. پس شانزده رئيس خاندان آبا از بني اَلِعازار و هشت رئيس خاندان آبا از بني ايتامار معين ايشان را بر حسب وکالت ايشان بر خدمت ايشان تقسيم کردند.۴
5 Wọ́n sì pín wọn láìṣègbè nípa yíya ìpín, nítorí àwọn olórí ibi mímọ́ àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run wà láàrín àwọn ọmọ méjèèjì Eleasari àti Itamari.
پس اينان با آنان به حسب قرعه معين شدند زيرا که رؤساي قدس و رؤساي خانه خدا هم از بني اَلِعازار و هم از بني ايتامار بودند.۵
6 Ṣemaiah ọmọ Netaneli, akọ̀wé ọ̀kan lára àwọn ọmọ Lefi sì kọ orúkọ wọn níwájú ọba àti àwọn ìjòyè: Sadoku àlùfáà, Ahimeleki ọmọ Abiatari àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà tí a mú láti ọ̀dọ̀ Eleasari àti ọ̀kan láti ọ̀dọ̀ Itamari.
و شَمَعيا ابن نَتَنئيل کاتب که از بني لاوي بود، اسمهاي ايشان را به حضور پادشاه و سروران و صادوق کاهن و اَخِيمَلَک بن ابياتار و رؤساي خاندان آباي کاهنان و لاويان نوشت و يک خاندان آبا به جهت اَلِعازار گرفته شد و يک به جهت ايتامار گرفته شد.۶
7 Ìpín èkínní jáde sí Jehoiaribu, èkejì sí Jedaiah,
و قرعه اول براي يهُوَياريب بيرون آمد و دوم براي يدَعيا،۷
8 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sì ni Harimu, ẹ̀kẹrin sì ní Seorimu,
و سوم براي حاريم و چهارم براي سعُوريم،۸
9 ẹ̀karùnún sì ni Malkiah, ẹlẹ́ẹ̀kẹfà sì ni Mijamini,
و پنجم براي مَلکيه و ششم براي مَيامين،۹
10 èkeje sì ni Hakosi, ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ sí ni Abijah,
و هفتم براي هَقُّوص و هشتم براي اَبِيا،۱۰
11 ẹ̀kẹsànán sì ni Jeṣua, ẹ̀kẹwàá sì ni Ṣekaniah,
و نهم براي يشُوع و دهم براي شَکُنيا،۱۱
12 ẹ̀kọkànlá sì ni Eliaṣibu, ẹlẹ́ẹ̀kẹjìlá sì ni Jakimu,
و يازدهم براي اَلياشيب و دوازدهم براي ياقيم،۱۲
13 ẹ̀kẹtàlá sì ni Hupa, ẹlẹ́ẹ̀kẹrìnlá sì ni Jeṣebeabu,
و سيزدهم براي حُفَّه و چهاردهم براي يشَبآب،۱۳
14 ẹ̀kẹdógún sì ni Bilgah, ẹ̀kẹrìndínlógún sì ni Immeri,
و پانزدهم براي بِلجَه و شانزدهم براي اِمير،۱۴
15 ẹ̀kẹtàdínlógún sì ni Hesiri, èkejìdínlógún sì ni Hafisesi,
و هفدهم براي حيزير و هجدهم براي هِفصيص،۱۵
16 ẹ̀kọkàndínlógún sì ni Petahiah, ogún sì ni Jeheskeli,
و نوزدهم براي فَتَحيا و بيستم براي يحَزقيئيل،۱۶
17 ẹ̀kọkànlélógún sì ni Jakini, ẹ̀kẹrìnlélógún sì ni Gamuli,
و بيست و يکم براي ياکين و بيست و دوم براي جامُول،۱۷
18 ẹ̀kẹtàlélógún sì ni Delaiah, ẹ̀kẹrìnlélógún sì ni Maasiah.
و بيست و سوم براي دَلايا و بيست و چهارم براي مَعَزيا.۱۸
19 Àwọn wọ̀nyí ni a yàn fún iṣẹ́ ìsìn nígbà tí wọ́n wọ ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ìlànà àti àṣẹ tí a ti fi fún wọn láti ọwọ́ baba ńlá wọn Aaroni gẹ́gẹ́ bí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí pàṣẹ fun un.
پس اين است وظيفه ها و خدمت هاي ايشان به جهت داخل شدن در خانه خداوند بر حسب قانوني که به واسطه پدر ايشان هارون موافق فرمان يهُوَه خداي اسرائيل به ايشان داده شد.۱۹
20 Ìyókù àwọn ọmọ Lefi. Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Amramu: Ṣubaeli láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Ṣubaeli; Jehdeiah.
و اما درباره بقيه بني لاوي، از بني عَمرام شُوبائيل و از بني شوبائيل يحَديا.۲۰
21 Àti gẹ́gẹ́ bí Rehabiah, láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Rehabiah, Iṣiah sì ni alákọ́kọ́.
و اما رَحَبيا. از بني رَحَبيا يشِياي رئيس،۲۱
22 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti; láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Ṣelomoti: Jahati.
و از بني يصهار شَلُومُوت و از بني شَلُومُوت يحَت.۲۲
23 Àwọn ọmọ Hebroni: Jeriah alákọ́kọ́, Amariah ẹlẹ́ẹ̀kejì, Jahasieli ẹlẹ́ẹ̀kẹta àti Jekameamu ẹlẹ́ẹ̀kẹrin.
و از بني حَبرُون يريا و دومين اَمَريا و سومين يحزيئيل و چهارمين يقمَعام.۲۳
24 Àwọn ọmọ Usieli: Mika; nínú àwọn ọmọ Mika: Ṣamiri.
از بني عُزّيئيل ميکا و از بني ميکا شامير.۲۴
25 Àwọn arákùnrin Mika: Iṣi; nínú àwọn ọmọ Iṣiah: Sekariah.
و برادر ميکا يشِيا و از بني يشِيا زکريا.۲۵
26 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi. Àwọn ọmọ Jaasiah: Beno.
و از بني مَراري مَحلي و مُوشِي و پسرِ يعزيابَنُو.۲۶
27 Àwọn ọmọ Merari. Láti Jaasiah: Beno, Ṣohamu, Sakkuri àti Ibri.
و از بني مَراري پسران يعزيا بَنُو و شُوهَم و زَکُّور و عِبري.۲۷
28 Láti Mahili: Eleasari, ẹni tí kò ni àwọn ọmọ.
و پسر مَحلي اَلِعازار و او را فرزندي نَبُود.۲۸
29 Láti Kiṣi. Àwọn ọmọ Kiṣi: Jerahmeeli.
و اما قَيس، از بني قَيس يرَحميئيل،۲۹
30 Àti àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti. Èyí ni àwọn ọmọ Lefi, gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn.
و از بني مُوشِي مَحلي و عادَر و يريمُوت. اينان بر حسب خاندان آباي ايشان بني لاوي مي باشند.۳۰
31 Wọ́n sì ṣé kèké gẹ́gẹ́ bí àwọn arákùnrin wọn àwọn ọmọ Aaroni ṣe ṣẹ́, níwájú ọba Dafidi àti Sadoku, Ahimeleki, àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ìdílé àgbàgbà arákùnrin wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀ lórí àwọn arákùnrin wọn kéékèèké.
ايشان نيز مثل برادران خود بني هارون به حضور داود پادشاه و صادوق و اَخِيمَلَک و رؤساي آباي کَهَنَه و لاويان قرعه انداختند يعني خاندانهاي آباي برادر بزرگتر برابر خاندانهاي کوچکتر او بودند.۳۱

< 1 Chronicles 24 >