< 1 Chronicles 23 >
1 Nígbà tí Dafidi sì dàgbà, tí ó sì di arúgbó, ó sì fi Solomoni ọmọ rẹ̀ jẹ ọba lórí Israẹli.
Na rĩrĩ, rĩrĩa Daudi aakũrire na agĩkorwo arĩ na mĩaka mĩingĩ-rĩ, agĩtua mũriũ Solomoni mũthamaki wa gũthamakĩra Isiraeli.
2 Ó sì kó gbogbo àgbàgbà Israẹli jọ, àti gẹ́gẹ́ bí àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi.
Ningĩ agĩcookanĩrĩria atongoria othe a Isiraeli hamwe na athĩnjĩri-Ngai na Alawii.
3 Àwọn ọmọ Lefi láti ọgbọ̀n ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ ni wọ́n kà àpapọ̀ iye àwọn ọkùnrin wọn sì jẹ́ ẹgbàá mọ́kàndínlógún.
Alawii arĩa maakinyĩtie mĩaka mĩrongo ĩtatũ kana makĩria magĩtarwo, nao arũme othe maarĩ 38,000.
4 Dafidi sì wí pe, ní ti èyí, ẹgbàá méjìlá ni kí wọn jẹ́ alábojútó iṣẹ́ ilé fún Olúwa àti ẹgbẹ̀rún mẹ́fà ni kí ó ṣe olórí àti onídàájọ́.
Daudi akiuga atĩrĩ, “Thĩinĩ wa aya, 24,000 nĩ marũgamagĩrĩre wĩra wa hekarũ ya Jehova, nao 6,000 matuĩke anene na atuithania a ciira.
5 Ẹgbàajì ni kí ó jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà àti ẹgbàajì ni kí o sì jẹ́ ẹni ti yóò máa yin Olúwa pẹ̀lú ohun èlò orin, mo ti ṣe èyí fún ìdí pàtàkì yìí.
Nao andũ 4,000 matuĩke arangĩri a ihingo, nao acio angĩ 4,000 matuĩke a kũgoocaga Jehova marĩ na inanda cia ũini iria heanĩte nĩ ũndũ wa wĩra ũcio kĩũmbe.”
6 Dafidi sì pín àwọn ọmọ Lefi sí ẹgbẹgbẹ́ láàrín àwọn ọmọ Lefi: Gerṣoni, Kohati àti Merari.
Daudi nĩagayanirie Alawii acio ikundi kũringana na ariũ a Lawi na nĩo Gerishoni, na Kohathu, na Merari.
7 Àwọn tí ó jẹ́ ọmọ Gerṣoni: Laadani àti Ṣimei.
Ariũ a Gerishoni maarĩ: Ladani na Shimei.
8 Àwọn ọmọ Laadani Jehieli ẹni àkọ́kọ́, Setamu àti Joẹli, mẹ́ta ní gbogbo wọn.
Ariũ a Ladani maarĩ: Jehieli na nĩwe warĩ mũtongoria wao, na Zethamu, na Joeli; othe maarĩ atatũ.
9 Àwọn ọmọ Ṣimei: Ṣelomiti, Hasieli àti Harani mẹ́ta ní gbogbo wọn. Àwọn wọ̀nyí sì ni olórí àwọn ìdílé Laadani.
Ariũ a Shimei maarĩ: Shelomothu, na Hazieli, na Harani, othe maarĩ atatũ. Acio nĩo maarĩ atongoria a nyũmba cia Ladani.
10 Àti ọmọ Ṣimei: Jahati, Sina, Jeuṣi àti Beriah. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Ṣimei mẹ́rin ni gbogbo wọn.
Na ariũ a Shimei maarĩ: Jahathu, na Ziza, na Jeushu, na Beria. Acio nĩo maarĩ ariũ a Shimei; othe maarĩ ana.
11 Jahati sì ni alákọ́kọ́ Sinah sì ni ẹlẹ́ẹ̀kejì, ṣùgbọ́n Jeuṣi àti Beriah kò ní àwọn ọmọ púpọ̀; bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ka ara wọn sí ìdílé kan pẹ̀lú ìfilé lọ́wọ́ kan.
Jahathu nĩwe warĩ mũtongoria wao, nake Ziza aarĩ mũnini wake, no Jeushu na Beria matiarĩ na ariũ aingĩ; nĩ ũndũ ũcio maatarirwo ta maarĩ a nyũmba ĩmwe, na makĩheo wĩra ũmwe.
12 Àwọn ọmọ Kohati: Amramu, Isari, Hebroni àti Usieli mẹ́rin ni gbogbo wọn.
Ariũ a Kohathu maarĩ: Amuramu, na Iziharu, na Hebironi, na Uzieli: othe maarĩ ana.
13 Àwọn ọmọ Amramu. Aaroni àti Mose. A sì ya Aaroni sọ́tọ̀ òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ títí láéláé, láti kọjú sí ohun mímọ́ jùlọ, láti fi rú ẹbọ sísun níwájú Olúwa, láti máa ṣe òjíṣẹ́ níwájú rẹ̀ àti láti kéde ìbùkún ní orúkọ rẹ̀ títí láéláé.
Ariũ a Amuramu maarĩ: Harũni na Musa. Harũni nĩamũrirwo hamwe na njiaro ciake nginya tene, nĩgeetha maamũrage indo iria theru mũno, na marutagĩre Jehova magongona, na mamũtungatagĩre, na marathimanage thĩinĩ wa rĩĩtwa rĩake nginya tene.
14 Àwọn ọmọ Mose ènìyàn Ọlọ́run ni wọ́n kà gẹ́gẹ́ bí apá kan ẹ̀yà Lefi.
Ariũ a Musa, mũndũ wa Ngai, maataranĩirio na mũhĩrĩga wa Lawi.
15 Àwọn ọmọ Mose: Gerṣomu àti Elieseri.
Ariũ a Musa maarĩ: Gerishomu na Eliezeri.
16 Àwọn ọmọ Gerṣomu: Ṣubaeli sì ni alákọ́kọ́.
Njiaro cia Gerishomu nĩ: Shebueli nĩwe warĩ mũtongoria wao.
17 Àwọn ọmọ Elieseri: Rehabiah sì ni ẹni àkọ́kọ́. Elieseri kò sì tún ní ọmọ mìíràn, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Rehabiah wọ́n sì pọ̀ níye.
Njiaro cia Eliezeri nĩ: Rehabia na nĩwe warĩ mũtongoria wao. Eliezeri ndaarĩ na ariũ angĩ, no ariũ a Rehabia maarĩ aingĩ mũno.
18 Àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti sì ni ẹni àkọ́kọ́.
Ariũ a Iziharu maarĩ: Shelomithu na nĩwe warĩ mũtongoria wao.
19 Àwọn ọmọ Hebroni: Jeriah sì ni ẹni àkọ́kọ́, Amariah sì ni ẹni ẹ̀ẹ̀kejì, Jahasieli sì ni ẹ̀ẹ̀kẹ́ta àti Jekameamu ẹ̀ẹ̀kẹrin.
Ariũ a Hebironi maarĩ: Jeria na nĩwe warĩ mũtongoria wao, na Amaria aarĩ wa keerĩ, na Jahazieli aarĩ wa gatatũ, na Jekameamu aarĩ wa kana.
20 Àwọn ọmọ Usieli: Mika ni àkọ́kọ́ àti Iṣiah ẹ̀ẹ̀kejì.
Ariũ a Uzieli maarĩ: Mika na nĩwe warĩ mũtongoria wao, nake Ishia aarĩ mũnini wake.
21 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi. Àwọn ọmọ Mahili: Eleasari àti Kiṣi.
Ariũ a Merari maarĩ: Mahali na Mushi. Ariũ a Mahali maarĩ: Eleazaru na Kishu.
22 Eleasari sì kú pẹ̀lú àìní àwọn ọmọkùnrin: Ó ní ọmọbìnrin nìkan. Àwọn ọmọ ẹ̀gbọ́n, àwọn ọmọ Kiṣi, sì fẹ́ wọn.
Eleazaru aakuire atarĩ na aanake; aarĩ o na airĩtu. Makĩhikio nĩ ariũ a mũrũ wa nyina na ithe wao Kishu.
23 Àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti mẹ́ta ni gbogbo wọn.
Ariũ a Mushi maarĩ: Mahali, na Ederi, na Jeremothu; othe maarĩ atatũ.
24 Àwọn wọ̀nyí sì ni ọmọ Lefi bí ìdílé wọn. Olórí ìdílé gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti fi orúkọ sílẹ̀ lábẹ́ orúkọ wọn, ó sì kà wọn ní ẹyọ kọ̀ọ̀kan, wí pé, àwọn òṣìṣẹ́ tí ó jẹ́ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ tí ń ṣiṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa.
Acio nĩo maarĩ njiaro cia Lawi kũringana na nyũmba ciao: na nĩo maarĩ atongoria a nyũmba ciao ta ũrĩa marĩĩtwa mao maandĩkĩtwo, na maatarirwo mũndũ o mũndũ, ũguo nĩ kuuga aruti a wĩra arĩa maarĩ na ũkũrũ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na makĩria, arĩa maatungataga hekarũ-inĩ ya Jehova.
25 Nítorí pé Dafidi ti sọ pé, “Níwọ̀n ìgbà tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ti fi ìsinmi fún àwọn ènìyàn tí ó kù tí sì ń gbé Jerusalẹmu títí láéláé,
Nĩgũkorwo Daudi nĩoigĩte atĩrĩ, “Kuona atĩ Jehova Ngai wa Isiraeli nĩaheete andũ ake ũhurũko, na nĩokĩte gũtũũra Jerusalemu nginya tene-rĩ,
26 àwọn ọmọ Lefi kò sì tún ru àgọ́ tàbí ọ̀kankan lára àwọn ohun èlò tí wọ́n ń lò níbi ìsìn rẹ̀.”
Alawii matigũcooka kũbatario nĩgũkuuaga hema ĩrĩa nyamũre kana kĩndũ o nakĩ kĩa iria ihũthagĩrwo cia gũtungata thĩinĩ wayo.”
27 Gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi sí, àwọn ọmọ Lefi, wọ́n sì kà wọ́n, bẹ̀rẹ̀ láti orí àwọn ọmọ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Kũringana na ciugo cia Daudi cia mũthia, Alawii arĩa maarĩ na ũkũrũ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ kana makĩria nĩmatarirwo.
28 Iṣẹ́ àwọn ọmọ Lefi ni láti ran àwọn ọmọ Aaroni lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ wọn fún ti ilé Olúwa: láti wà lábẹ́ ìkáwọ́ agbára ìlú, àti ẹ̀gbẹ́ ilé, àti ìwẹ̀nùmọ́ ti gbogbo ohun ìyàsọ́tọ̀ àti ṣíṣe ohun tí í ṣe iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa.
Wĩra wa Alawii warĩ wa gũteithia njiaro cia Harũni ũtungata-inĩ wa hekarũ ya Jehova ta ũũ: kũrũgamĩrĩra nja cia hekarũ na tũnyũmba twa ithaku-inĩ, na gũtherithia indo iria nyamũre, na kũruta mawĩra marĩa mangĩ thĩinĩ wa nyũmba ya Ngai.
29 Wọ́n sì wà ní ìkáwọ́ àkàrà tí wọ́n mú jáde láti orí tábìlì, àti ìyẹ̀fun fún ẹbọ, àti àkàrà aláìwú, àti fún púpọ̀ àti èyí tí a pòpọ̀, àti gbogbo onírúurú ìwọ̀n àti wíwọ̀n àti òsùwọ̀n.
Nĩo maarĩ arũgamĩrĩri a mĩgate ĩrĩa yaigagwo metha-inĩ, na maruta ma mũtu wa ngano, na tũmĩgate tũrĩa tũtarĩ na ndawa ya kũimbia, na wĩra wa gũkanda na kũruga mĩgate, na mawĩra mothe ma gũthima ũingĩ na mũigana wa indo.
30 Wọ́n sì gbọdọ̀ dúró ní gbogbo òwúrọ̀ láti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa. Wọ́n sì gbọdọ̀ ṣe irú kan náà ní àṣálẹ́.
Ningĩ marũgamage o rũciinĩ gũcookeria Jehova ngaatho na kũmũgooca. Ningĩ magekaga ũguo o hwaĩ-inĩ,
31 Àti láti rú ẹbọ sísun fún Olúwa ní ọjọ́ ìsinmi àti ní àsìkò oṣù tuntun àti ní àjọ̀dún tí a yàn. Wọ́n gbọdọ̀ sìn níwájú Olúwa lójoojúmọ́ ní iye tó yẹ àti ní ọ̀nà tí a ti pàṣẹ fún wọn.
na rĩrĩa rĩothe maruta ma njino mangĩarutĩirwo Jehova, mĩthenya ya Thabatũ, na ciathĩ cia Karũgamo ka Mweri, na ciathĩ iria ingĩ ciathanĩtwo. No nginya matungatage mbere ya Jehova mahinda mothe marĩ mũigana ũrĩa ũtuĩtwo, ningĩ na njĩra ĩrĩa maathĩtwo marutage nayo.
32 Bẹ́ẹ̀ ni nígbà náà, àwọn ọmọ Lefi gbé ìgbékalẹ̀ jáde fún ìpàdé àgọ́, fún Ibi Mímọ́ àti, lábẹ́ àwọn arákùnrin àwọn ọmọ Aaroni fún ìsìn ilé Olúwa.
Na nĩ ũndũ ũcio Alawii magĩthiĩ na mbere kũruta wĩra ũrĩa mehokeirwo wa Hema-ya-Gũtũnganwo, na wa Handũ-harĩa-Hatheru, matongoretio nĩ ariũ a ithe wao a rũciaro rwa Harũni, nĩ ũndũ wa ũtungata wa hekarũ ya Jehova.