< 1 Chronicles 20 >

1 Ní àkókò àkọ́rọ̀ òjò, ni ìgbà tí àwọn ọba lọ sí ogun, Joabu ṣamọ̀nà àwọn ọ̀wọ́ ọmọ-ogun. Ó fi ilẹ̀ àwọn ará Ammoni ṣòfò. Ó lọ sí ọ̀dọ̀ Rabba. Ó sì fi ogun dúró tì í. Ṣùgbọ́n Dafidi dúró sí Jerusalẹmu Joabu kọlu Rabba, ó sì fi sílẹ̀ ní ìparun.
Hagi aisimo'ma vagaregeno trazamo'ma agatama nehagea knarera kini vahe'mo'za ha' ome nehaza knagino, ana knama egeno'a Joapu'a Israeli sondia vahetmina zamavareno Amoni vahe' mopafi hara ome hu'naze. Hagi ana hapina Amoni vahera hara huzmagatere'za Raba rankumazmia zamahe'za hanare'naze. Hianagi Deviti'a ana hatera ovu Jerusalemi kumate mani'ne.
2 Dafidi mú adé kúrò lórí àwọn ọba wọn ìwọ̀n rẹ̀ dàbí i tálẹ́ǹtì wúrà, a sì tò ó jọ pẹ̀lú àwọn òkúta iyebíye. A sì gbé e ka orí Dafidi. Ó kó ọ̀pọ̀ ìkógun láti ìlú ńlá náà.
Hagi Deviti'ma Raba kumate'ma ne-eno, Amoni vahe kini ne'mofo kini fetorira emerino agra asenire antani'ne. Hagi ana fetorira 34 kilo hu'nea golinu tro huno agu'afina zago'amo marerirfa haverami ante'ne. Hagi ana rankumapintira eri havizama haza zantamina rama'a zagone fenonena Deviti'a eri'ne.
3 Ó sì kó gbogbo àwọn ènìyàn tí ó wà ní ibẹ̀ jáde, ó sì fi iṣẹ́ lé wọn lọ́wọ́ láti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ayùn àti ìtulẹ̀ onírin àti àáké. Dafidi ṣe eléyìí sí gbogbo àwọn ará ìlú Ammoni. Nígbà náà, Dafidi àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ padà sí Jerusalẹmu.
Ana nehuno Raba kumate vahetmina kazokzo eri'za vahe zamavarege'za so nuti'ma piki tunteti'ma, saumereti'ma eri'zama eri vahe zamavarentege'za eri'zana eri'naze. Hagi maka Amoni vahetmimofo rankumapi vahetmina ana zanke huzmanteteno, Deviti'ene maka sondia vahe'anena ete Jerusalemi kumate vu'naze.
4 Ní ẹ̀yìn èyí ni ogun bẹ́ sílẹ̀ ní Geseri pẹ̀lú àwọn ará Filistini, ní àkókò yìí ni Sibekai ará Huṣati pa Sipai, ọ̀kan lára àwọn ọmọ Refaimu, àti àwọn ará Filistini ni a ṣẹ́gun.
Hagi ana'ma hutegeno'a, Israeli sondia vahe'mo'za Gezeri kumate Filistia vahetamina hara ome huzmante'naze. Hagi ana ha'ma hazafi Husa nagapinti ne' Sibekai'a Refaimi nagapinti Sipa'ema nehaza nera ahe fri'ne. Hagi Sipai'a tusinasi vahetmimofo zamagehe'mokino agri'ma ahete'za Filistia vahetmina hara huzmagatere'naze.
5 Nínú ogun mìíràn pẹ̀lú àwọn ará Filistini, Elhanani ọmọ Jairi pa Lahmi arákùnrin Goliati ará Gitti, ẹni ti ó ní ọ̀kọ̀ kan tí ó dàbí ọ̀pá ahunṣọ.
Hagi ru zupa ete mago'ane Israeli sondia vahe'mo'za Filistia vahera hara ome huzmantazageno, Jairi nemofo Elhana'a Gati kumateti ne' Goliati nefu Lamina ahegeno fri'ne. Hagi ana nekrerfamofo karugru zotamo'a tavaravema troma nehaza masinimofo zafa'agna hu'ne.
6 Síbẹ̀síbẹ̀ nínú ogun mìíràn, tí ó wáyé ní Gati, ọkùnrin títóbi kan wà tí ó ní ìka mẹ́fà ní ọwọ́ rẹ̀ pẹ̀lú ìka mẹ́fà ní ẹsẹ̀ rẹ̀ mẹ́rìnlélógún lápapọ̀. Òun pẹ̀lú wá láti Rafa.
Hagi mago'ane Israeli sondia vahe'mo'za Gati kumatera hara ome nehu'za, 6si'a azankogi, 6si'a agigo huntegeno ana maka 24'a agigo azanko hunte'nea nekrerfa ke'za erifore hu'naze. Hagi ana nera Rafa vahepinti tusinasi vahetmimofo zamagehe'mo'e.
7 Nígbà tí ó fi Israẹli ṣẹ̀sín, Jonatani ọmọ Ṣimea, arákùnrin Dafidi sì pa á.
Hagi ana ne'mo'a Israeli vahera huprihuno ki'za zokagoke huzmantegeno Deviti nefu Simea nemofo Jonatani ana nekrerfa ahegeno fri'ne.
8 Wọ̀nyí ni ìran ọmọ Rafa ní Gati, wọ́n sì ṣubú sí ọwọ́ Dafidi àti àwọn ọkùnrin rẹ̀.
Hagi e'i ana maka vahetmina tusinasi vahetmimpinti fore hu'za e'naza vahetminkino, Deviti'ene sondia vahe'aramimozane zamahe vagare'naze.

< 1 Chronicles 20 >