< 1 Chronicles 17 >

1 Lẹ́yìn ìgbà tí Dafidi ti fi ìdí kalẹ̀ sínú ààfin rẹ̀, ó sọ fún Natani wòlíì pé, “Èmi nìyí, tí ń gbé inú ààfin kedari nígbà tí àpótí ẹ̀rí Olúwa wà lábẹ́ àgọ́.”
A IA i ko Davida noho ana iloko o kona hale, olelo mai la o Davida ia Natana ke kaula, Eia au ke noho nei iloko o ka hale kedera, aka, o ka pahuberita o Iehova, aia no ia malalo o na paku.
2 Natani dá Dafidi lóhùn pé, “Ohunkóhun tí o bá ní lọ́kàn, ṣe é nítorí tí Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ.”
Alaila, i aku la o Natana ia Davida, E hana oe i ka mea a pau maloko o kou naau; no ka mea, me oe pu no ke Akua.
3 Ní àṣálẹ́ ọjọ́ náà, ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tọ Natani wá, wí pé:
A ia po iho no, hiki mai la ka olelo a ke Akua ia Natana, i mai
4 “Lọ sọ fún ìránṣẹ́ mi Dafidi, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Ìwọ kò gbọdọ̀ kọ́ ilé fún mi láti máa gbé.
E hele aku oe, e hai ia Davida i kuu kauwa, Penei ka Iehova i olelo mai nei, Mai hana oe i hale no'u e noho ai:
5 Èmi kò tí ì gbé nínú ilé láti ọjọ́ tí mo ti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti títí di òní yìí. Èmi ń lọ láti àgọ́ dé àgọ́ àti láti ibùgbé dé ibùgbé.
No ka mea, aole au i noho iloko o ka hale maoli, mai ka manawa mai a'u i kai mai nei i ka Iseraela a hiki i keia manawa: aka, ua hele au mai kekahi halelole, a hiki i kekahi halelole, a mai kekahi halelewa a kekahi halelewa.
6 Ni ibi gbogbo tí mo ti bá gbogbo Israẹli rìn dé, ǹjẹ́ mo wí nǹkan kan sí ọ̀kan nínú àwọn adarí Israẹli, tí èmí pàṣẹ fún láti máa jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn àwọn ènìyàn mi, wí pé, “Kí ní ṣe tí ẹ̀yin kò fi kọ́ ilé tí a fi igi kedari kọ́ fún mi?”’
I na wahi a'u i hele pu ai me ka Iseraela a pau, i olelo anei au i kekahi lunakanawai o ka Iseraela, a'u i kauoha aku ai e hanai i ko'u poe kanaka, i ka i ana aku, No ke aha la oukou i hana ole ai i hale kedera no'u!
7 “Nígbà náà, sọ fún ìránṣẹ́ mi Dafidi pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: Èmi mú ọ kúrò ní pápá oko tútù wá, àní kúrò lẹ́yìn agbo àgùntàn, kí ìwọ kí ó lè máa ṣe olórí àwọn ènìyàn mi Israẹli.
Nolaila la, e olelo aku oe i kuu kauwa ia Davida, Eia ka Iehova o na kaua i olelo mai nei, I lawe mai no wau ia oe mai ka pahipa mai, mamuli mai hoi o ka poe hipa, i alii oe maluna o ko'u poe kanaka o ka Iseraela;
8 Èmi ti wà pẹ̀lú rẹ ní, ibikíbi tí ìwọ bá lọ, èmí sì ti gé gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ kúrò níwájú rẹ. Nísinsin yìí Èmi yóò mú kí orúkọ rẹ kí ó dàbí orúkọ àwọn ènìyàn ńlá jùlọ tí ó wà ní ayé.
Owau no kekahi pu me oe i na wahi a pau au i hele ai, a ua hooki iho no wau i na enemi ou a pau mai kou maka aku, a ua hookaulana au i kou inoa, e like me ka inoa o na kanaka nui ma ka honua nei.
9 Èmi yóò sì pèsè ààyè kan fún àwọn ènìyàn mi Israẹli, kí wọn kí ó lè ní ilé tiwọn, kí a má sì ṣe dààmú wọn mọ́. Àwọn ènìyàn búburú kì yóò ni wọ́n lára mọ́, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ṣe ní ìbẹ̀rẹ̀.
Na'u hoi e hoike aku i wahi no ko'u poe kanaka no ka Iseraela, a e kanu iho no au ia lakou, a e noho iho lakou ma ko lakou wahi, aole e nee hou aku lakou; aole hoi e hoopoino hou mai ka poe keiki na ka hewa ia lakou, e like mamua,
10 Bí wọ́n sì ti ṣe láti ìgbà tí mo ti yan àwọn aṣáájú lórí àwọn ènìyàn mi Israẹli. Èmi pẹ̀lú yóò ṣẹ́gun gbogbo àwọn ọ̀tá yín. “‘Èmi sọ fún yín pé Olúwa yóò kọ́ ilé kan fún yín,
A mai ka manawa mai a'u i hoonoho ai i na lunakanawai maluna o ko'u poe kanaka o ka Iseraela. Eia hoi, na'u no e hoopau auanei i kou poe enemi a pau. A eia hoi kekahi, ke, hai aku nei au ia oe, na Iehova no e hana i hale nou.
11 nígbà ti ọjọ́ rẹ bá kọjá, tí ìwọ bá lọ láti lọ bá àwọn baba à rẹ, Èmi yóò gbé àwọn ọmọ rẹ sókè láti rọ́pò rẹ, ọ̀kan lára àwọn ọmọ tìrẹ, Èmi yóò sì fìdí ìjọba rẹ̀ kalẹ̀.
A i ka manawa i hala ae kou mau la, a hele oe me ou mau makua, na'u no e hooku ae i kau hua mahope ou, no na keiki au; a e hookupaa auanei au i kona aupuni.
12 Òun ni ẹni tí yóò kọ́ ilé fún mi, èmi yóò sí fi ìdí ìtẹ́ rẹ̀ kalẹ̀ títí láé.
Nana no e hana i hale no'u, a e hookupaa mau loa auanei au i kona nohoalii.
13 Èmi yóò jẹ́ baba rẹ̀, Òun yóò sì jẹ́ ọmọ mi. Èmi kì yóò mú ìfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ láéláé gẹ́gẹ́ bí mo ṣe mú un kúrò lọ́dọ̀ àwọn aṣáájú rẹ̀.
Owau auanei kona makua, a e lilo oia i keiki na'u: aole au e lawe aku i kuu aloha mai ona aku, me a'u i lawe aku ai ia mai kou mua aku.
14 Èmi yóò gbé e ka orí ilé mi àti ìjọba mi títí láé; ìtẹ́ rẹ̀ ni a ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ títí láé.’”
Aka, e hoonoho au ia ia maloko o kuu hale a iloko o kuu aupuni a mau loa aku; a e hookupaa mau loa ia kona nohoalii.
15 Natani ròyìn fún Dafidi gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ ti ìfihàn yí.
Ma neia mau huaolelo a pau, a ma keia hihio a pau, ka Natana i olelo aku ai ia Davida.
16 Nígbà náà, ọba Dafidi wọlé lọ, ó sì jókòó níwájú Olúwa ó sì wí pé, “Ta ni èmi, Olúwa Ọlọ́run, àti ki ni ìdílé mi, tí ìwọ mú mi dé ibí?
A hele aku la o Davida ke alii, a noho aku la imua o Iehova, olelo aku la, Owai la wau, e Iehova ke Akua, heaha hoi ka'u ohana i malama mai ai oe ia'u a hiki i neia wa?
17 Pẹ̀lú bí ẹni pé èyí kò tó lójú rẹ, Ọlọ́run, ìwọ ti sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ iwájú ilé ìránṣẹ́ rẹ. Ìwọ ti wò mí bí ẹni pé èmi ni ẹni gbígbéga jù láàrín àwọn ọkùnrin Olúwa Ọlọ́run.
He mea uuku hoi keia imua o kou maka, e ke Akua: a ua olelo mai hoi oe no ka ohana a kau kauwa a liuliu aku mahope; a ua hoomanao mai oe ia'u ma ka ke kanaka kiekie, e Iehova ke Akua.
18 “Kí ni ohun tí Dafidi tún lè sọ nítorí ọlá tí o bù fún ìránṣẹ́ rẹ? Nítorí tí ìwọ mọ ìránṣẹ́ rẹ,
Heaha ka mea hou aku e hiki ia Davida ke olelo aku ia oe no ka pono o kau kauwa? no ka mea, ua ike oe i kau kauwa.
19 Olúwa. Nítorí ti ìránṣẹ́ rẹ àti gẹ́gẹ́ bí àṣẹ rẹ, ìwọ ti ṣe ohun ńlá yìí àti láti fi gbogbo ìlérí ńlá yìí hàn.
E Iehova, no ka pono o kau kauwa, a e like me ko loko o kou naau, ua hana mai oe i keia mea nui a pau, ma ka hoike ana mai i na mea nui a pau.
20 “Kò sí ẹnìkan bí rẹ Olúwa, kò sì sí Ọlọ́run kan àfi ìwọ, gẹ́gẹ́ bí à ti gbọ́ pẹ̀lú etí ara wa.
E Iehova e, aohe ou mea like, aohe Akua e ae, o oe wale no, ma ka mea a pau a makou i lohe ai ma ko makou pepeiao.
21 Pẹ̀lú ta ni ó dàbí àwọn ènìyàn rẹ Israẹli—orílẹ̀-èdè kan ní ayé, tí Ọlọ́run jáde lọ láti ra àwọn ènìyàn kan padà fún ara rẹ̀, àti láti lè ṣe orúkọ fún ara à rẹ, àti láti ṣe ohun ńlá àti ọwọ́ ìyanu nípa lílé àwọn orílẹ̀-èdè kúrò níwájú àwọn ènìyàn rẹ̀, ẹni tí ó gbàlà láti Ejibiti?
Auhea la kekahi lahuikanaka ma ka honua nei e like me kou poe kanaka o ka Iseraela, ka poe a ke Akua i kii aku ai e hoola i poe kanaka nona, i mea e kaulana ai kou inoa i nui ia, a i weliweli, ma ka hookuke ana aku i na lahuikanaka mai ke alo aku o kou poe kanaka au i hoola ai mai Aigupita mai?
22 Ìwọ ṣe àwọn ènìyàn rẹ Israẹli ní tìrẹ láéláé ìwọ Olúwa sì ti di Ọlọ́run wọn.
No ka mea, ua hoolilo oe i kou poe kanaka ka Iseraela i poe kanaka nou, a mau loa aku: a ua lilo mai oe, e Iehova, i Akua no lakou.
23 “Nísinsin yìí, Olúwa, jẹ́ kí ìlérí tí ìwọ ti ṣe fún ìránṣẹ́ rẹ àti ilé rẹ̀ di fífi ìdí múlẹ̀ títí láé. Ṣe gẹ́gẹ́ bí o ti ṣe ìlérí.
Nolaila hoi, e Iehova, e hookupaa mau loa oe i ka olelo au i olelo mai ai no kau kauwa, a me kana ohana, a e hana mai e like me kau i olelo ai.
24 Kí ó lè di fífi ìdí múlẹ̀ àti kí orúkọ rẹ di gbígbéga títí láé. Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin yóò wí pé, ‘Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ni Ọlọ́run Israẹli.’ Ilé ìránṣẹ́ rẹ Dafidi sì ni a ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ níwájú rẹ.
Oiaio, e hookupaa oe, i hoonui mau loa ia kou inoa, i ka i ana, O Iehova o na kana, oia ke Akua o ka Iseraela, ke Akua ia i ka Iseraela: a e hookupaaia ka ohana a kau kauwa a Davida imua ou.
25 “Ìwọ, Ọlọ́run mi, ti fihan ìránṣẹ́ rẹ pé, ìwọ yóò kọ́ ilé fún un. Bẹ́ẹ̀ ni ìránṣẹ́ rẹ ti ní ìgboyà láti gbàdúrà sí ọ.
No ka mea, ua hoike mai oe, e kuu Akua, i ka pepeiao o kau kauwa, e hana oe i hale nona; nolaila, ua manao iho kau kauwa e pule aku imua ou.
26 Olúwa, ìwọ ni Ọlọ́run. Ìwọ ti fi ìlérí dídára yìí fún ìránṣẹ́ rẹ.
Ano hoi, e Iehova, o oe no ke Akua, a ua hai mai oe i keia lokomaikai i kau kauwa:
27 Nísinsin yìí ó ti tẹ́ ọ lọ́rùn láti bùkún ilé ìránṣẹ́ rẹ kí ó lè tẹ̀síwájú ní ojú rẹ; nítorí ìwọ, Olúwa, ti bùkún un, a ó sì bùkún un títí láéláé.”
Nolaila hoi, ua lealea oe e hoopomaikai mai i ka ohana a kau kauwa, i mau loa ia imua ou: no ka mea, ke hoopomaikai mai nei oe, e Iehova, a e pomaikai mau loa no ia.

< 1 Chronicles 17 >