< 1 Chronicles 16 >
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
Hottelah Cathut e thingkong teh a thokhai awh teh, hruek nahanelah Devit ni rim a yap pouh e dawkvah a hruek awh. Hmaisawi thuengnae, roum thuengnae naw hah Cathut koe e poe awh.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
Devit ni hmaisawi thuengnae, roum thuengnae naw hah a poe hoiyah BAWIPA e min lahoi taminaw hah yawhawinae a poe.
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
Isarelnaw pueng teh, napui tongpa abuemlah vaiyei atueng buet touh hoi moituen buet touh, misurphen buet touh rip a poe.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
Isarel BAWIPA Cathut pahnim hoeh nahan, lunghawilawk dei e, hoi pholen nahanelah, BAWIPA e thingkong hmalah, thaw ka tawk lah Levihnaw tangawn hah a rawi awh.
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
Kahrawikung lah Asaph, apâhni lah ratoung ka kueng e Zekhariah, Jeiel, Shemiramoth, Jehiel, Mattithiah, Eliab, Benaiah, Obededom, Jeiel ni ratoung hoi tamawi a tum, Asaph cecak a khawng.
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
Vaihma Benaiah hoi Jahaziel ni Cathut e lawkkam thingkong e hmalah mongka kamrawicalah a ueng roi.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
Hot nah hnin hoi BAWIPA koe lunghawilawk dei hane Devit ni hete la heh Asaph hoi a hmaunawngha koe hmaloe poung lah a poe.
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀, ẹ fi iṣẹ́ rẹ̀ hàn nínú àwọn ènìyàn fún ohun tí ó ṣe
Oe BAWIPA koevah lunghawilawk dei awh nateh, a min lahoi hram awh. Miphunnaw pueng koe a sak e hno hah panuek sak awh.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i, ẹ sọ ti gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.
Ama koe la sak awh haw, oupnae hoi ama teh pholen awh. A sak e hno kângairunae pueng hah dei awh.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́; jẹ kí ọkàn àwọn tí ó yin Olúwa kí ó yọ̀.
A min kathoung hah oup awh. BAWIPA ka tawng e naw a lungthinnaw teh hawi awh naseh.
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀; e wá ojú rẹ̀ nígbà gbogbo.
BAWIPA e thasainae tawng awh haw, A minhmai hah hoe tawng awh.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe, iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ àti ìdájọ́ tí Ó ti sọ.
A sak e kâgairu hnonaw hah pahnim awh hanh. A sak e kângairunae hoi a pahni dawk hoi lawkcengnae hai.
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn ọmọ Jakọbu, ẹ̀yin tí ó ti yàn.
Oe a san Isarel catounnaw, a rawi e tami Jakop catounnaw,
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa; ìdájọ́ rẹ̀ wà ní gbogbo ayé.
Ama teh BAWIPA Cathut lah ao. A lawkcengnae teh talai van abuemlah dawk kâ a tawn.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé, ọ̀rọ̀ tí ó pàṣẹ, fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìran,
A lawk kam hah a yungyoe pâkuem awh haw, se 1000 totouh lawk a kam e naw hah.
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu, ìbúra tí ó ṣe pẹ̀lú fún Isaaki.
Abraham koe lawk a kam e naw hah, Isak koe lawk a kam e naw hah,
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ sí Israẹli, gẹ́gẹ́ bi májẹ̀mú ayérayé:
Hot patetlah Jakop koe kâlawknaw a cak sak, Isarelnaw koe yungyoe e lawkkam pouh e hah a cak sak.
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani. Gẹ́gẹ́ bí ààyè tí ìwọ yóò jogún.”
Kanaan ram teh na coe e râw lah na poe awh han telah a ti.
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye, wọ́n kéré gidigidi, wọ́n sì jẹ́ àlejò níbẹ̀,
Tami kayounca lah na o awh, Oe tami younca, imyin patetlah ka o awh navah,
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè láti ìjọba kan sí èkejì.
miphun tangkuem koe hmanghmang kâva e lah, uknaeram tangkuem hoi miphun tangkuem koe,
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú; nítorí tiwọn, ó bá àwọn ọba wí.
Apinihai ka pacekpahlek hanlah pasoung hoeh. Ahnimouh kecu dawk siangpahrangnaw hai a yue awh.
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi; má ṣe pa àwọn wòlíì mi lára.”
Satui ka awi e hah tek awh hanh awh, kaie profetnaw hah patawnae poe awh hanh haw telah a ti.
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé; ẹ máa fi ìgbàlà rẹ̀ hàn láti ọjọ́ dé ọjọ́.
Talai taminaw pueng ni BAWIPA pholennae la sak awh nateh, hnintangkuem vah rungngangnae lawk hah pathang awh haw.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ohun ìyàlẹ́nu tí ó ṣe láàrín gbogbo ènìyàn.
Miphun tangkuem koe a bawilennae hah dei awh nateh, tami tangkuem koe a sak e kângairunae pathang awh.
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ; òun ni kí a bẹ̀rù ju gbogbo àwọn Ọlọ́run lọ.
BAWIPA teh a bawilen poung dawkvah, pholen hanelah ao. Ama teh Cathut pueng hlak vah taki hanelah ao.
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà, ṣùgbọ́n Olúwa dá àwọn ọ̀run.
Bangkongtetpawiteh, miphun alouke cathutnaw teh, meikaphawknaw doeh. Hateiteh, BAWIPA ni kalvan teh a sak.
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀; agbára àti ayọ̀ ni ó wà ní ibi ibùgbé rẹ̀.
Barinae hoi taluenae teh a hmalah ao. A thaonae hoi lunghawinae ama koe ao.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè, ẹ fi ògo àti ipá fún Olúwa.
Oe miphunnaw hoi imthungnaw pueng BAWIPA koe poe awh, BAWIPA koe bawilennae hoi a thasainae hah poe awh.
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀; gbé ọrẹ kí ẹ sì wá síwájú rẹ̀. Sìn Olúwa nínú inú dídùn ìwà mímọ́ rẹ̀.
BAWIPA teh a min hoi kamcu e bawilennae poe awh. Poe hanlah kaawm e pueng sin awh nateh, a hmalah tâcawtkhai awh. A meihawinae thoungnae hoi BAWIPA teh bawk awh.
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé! Ayé sì fi ìdí múlẹ̀; a kò sì le è ṣí i.
Talai taminaw pueng amae hmalah pâyaw awh. Kâhuet thai hoeh nahanlah talaivan teh a cak sak.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn; lẹ́ kí wọn kí ó sọ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, pé “Olúwa jẹ ọba!”
Kalvannaw hai lunghawi naseh, talai hai lunghawi naseh, BAWIPA ni a uk telah miphun tangkuem koe pathang awh.
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀; Jẹ́ kí àwọn pápá kí ó hó fún ayọ̀, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀!
Tuipui hoi a thung kaawm e pueng ni hram awh naseh, law hoi a thung kaawm e pueng ni lunghawi awh naseh.
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin, wọn yóò kọrin fún ayọ̀ níwájú Olúwa, nítorí tí ó wá láti ṣèdájọ́ ayé.
Kahrawng e thing kaawm e pueng ni BAWIPA e hmalah lunghawi nalaihoi la a sak awh han. Bangkongtetpawiteh, talai dawk lawkceng hanelah a tho han.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára; ìfẹ́ ẹ rẹ̀ dúró títí láé.
Oe BAWIPA koevah, lunghawinae lawk dei awh. Bangkongtetpawiteh, ama teh ahawi. A lungmanae teh a yungyoe a kangning.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa; kó wa jọ kí o sì gbà wá kúrò lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè, kí àwa kí ó lè fi ọpẹ́ fún orúkọ mímọ́ rẹ, kí àwa kí ó lè yọ̀ nínú ìyìn rẹ̀.”
Oe kaimae Rungngangnae Cathut na rungngang haw, ka thoung e na min pholen hane hoi, na pholennae hoi tâ hanelah, Jentelnaw thung hoi na rungngang haw. Cungtalah na pâkhueng haw tet awh naseh.
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, láé àti láéláé. Lẹ́yìn náà gbogbo àwọn ènìyàn wí pé, “Àmín,” wọ́n “Yin Olúwa.”
Yungyoe hoi yungyoe totouh Isarel BAWIPA Cathut teh, pholennae awm lawiseh, tami pueng ni Amen ati awh teh, BAWIPA teh a pholen awh.
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
Hatdawkvah, BAWIPA lawkkam thingkong hma lae hnintangkuem a panki e patetlah thaw ka tawk hane Asaph hoi a hmaunawnghanaw a ta.
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
Obededom hoi a hmaunawngha 68 touh ni a kabawp awh vaiteh, Jeduthun capa Obededom hoi Hosah teh longkha ka ring hanelah ao han.
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
BAWIPA ni Isarelnaw kâ a poe BAWIPA e kâlawk dawk thut e patetlah hmaisawi thuengnae khoungroe dawkvah, amom tangmin Gibeon hmuenrasang dawk,
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
BAWIPA e lukkareiim hmalah, sathei thuengnae meng ka poe hanelah, vaihma Zadok hoi a hmaunawngha vaihma lah a rawi awh.
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
Amae pahrennae teh, a yungyoe a kangning dawkvah, BAWIPA koe lunghawi lawk dei hanelah, Heman hoi Jeduthun, hoi alouke taminaw hoi rawi e lah ao awh.
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
Heman hoi Jeduthun teh mongka cecak, kacai e phunkuepnaw hoi cungtalah tumkhawng hane ka khenyawn hanelah ao awh.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
Hahoi tami pueng teh ama im lengkaleng a ban awh teh, Devit hai a imthungkhunaw yawhawi poe hanelah a ban van.