< 1 Chronicles 16 >

1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
Ilia da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amo gaguli asili, Da: ibidi ea hamoi Abula Diasu amo ganodini sali. Amalalu, ilia da gobele salasu amola Hahawane Gilisili Olofole Iasu Godema nodoma: ne hamoi.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
Da: ibidi da ilia iasu liligi huluane gobele sanawene, e da Hina Gode Ea Dioba: le, Gode da Isala: ili dunuma hahawane dogolegele ima: ne sia: ne gadoi.
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
E da ilima ha: i manu sagoi. E da Isala: ili dunu amola uda afae afae ilima agi ga: gi afae, hu dadamoi afae amola hafogai waini fage sagoi.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
Da: ibidi da Lifai fi dunu mogili, Isala: ili fi ilia Hina Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amo midadi, Godema nodone sia: ne gadosu amola gesami hea: su amo ouligima: ne, ilegei.
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
E da A: isa: fe ouligisudafa ilegei (A: isa: fe da giga: mesa duma: ne ilegei). Ea fidisu dunu da Segalaia. Eno ouligisu dunu da, Yiaiele, Similamode, Yihaiele, Ma: didaia, Ilaia: be, Bina: ia, Oubede Idome amola Yiaiele. Amo dunu da sani baidama duma: ne ilegei.
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
Da: ibidi da gobele salasu dunu aduna amo Bina: ia amola Yaha: isiele, eso huluane Gode Ea Gousa: su Sema Gagili midadi dalabede fulaboma: ne ilegei.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
Amo esoga, Da: ibidi da degabo agoane, A:isa: fe amola Lifai fi dunu eno, amo Godema nodone gesami hea: ma: ne ilegei.
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀, ẹ fi iṣẹ́ rẹ̀ hàn nínú àwọn ènìyàn fún ohun tí ó ṣe
Hina Godema nodone sia: ma! Ea gasa bagade hou olelema! Fifi asi gala huluane ilima Ea hamobe olelema!
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i, ẹ sọ ti gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.
Hina Godema nodone gesami hea: le ima! Amola liligi noga: idafa Ea hamoi amo adodoma.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́; jẹ kí ọkàn àwọn tí ó yin Olúwa kí ó yọ̀.
Nini da Ea fi dunuba: le, Ema nodoma. Amola dunu huluane Ema fa: no bobogebe da nodone sia: ma: ma.
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀; e wá ojú rẹ̀ nígbà gbogbo.
Hina Gode Ea fidima: ne masa, amola Ema mae yolele nodonanoma.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe, iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ àti ìdájọ́ tí Ó ti sọ.
Dilia da Gode Ea hawa: hamosu dunu A: ibalaha: me amola Ya: igobe, Hi ilegele lai, egaga fifi mana. Dilia da Gode Ea musa: degabo hame ba: su hou hamoi amo dawa: ma, amola se imunusa: fofada: su Ea hamoi, amo bu dawa: ma.
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn ọmọ Jakọbu, ẹ̀yin tí ó ti yàn.
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa; ìdájọ́ rẹ̀ wà ní gbogbo ayé.
Hina Gode da ninia Gode. Ea hamoma: ne sia: i, E da osobo bagade fifi asi huluane ilima sia: i.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé, ọ̀rọ̀ tí ó pàṣẹ, fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìran,
E da Ea Gousa: su Sema hamoi amo eso huluane mae fisili ouligilalumu. E hamomusa: ilegei da fifi manebe 1,000 agoane bobaligila misunu, ilima dialumu.
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu, ìbúra tí ó ṣe pẹ̀lú fún Isaaki.
E da A: ibalahame amola Aisage elama hamomusa: ilegele sia: i, amo E da gagui dialumu.
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ sí Israẹli, gẹ́gẹ́ bi májẹ̀mú ayérayé:
Hina Gode da Ya: igobema eso huluane dialoma: ne gousa: su hamoi.
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani. Gẹ́gẹ́ bí ààyè tí ìwọ yóò jogún.”
E amane ilegele sia: i, “Na da Ga: ina: ne soge dima imunu. Amo soge da di fawane gaguli dialumu.”
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye, wọ́n kéré gidigidi, wọ́n sì jẹ́ àlejò níbẹ̀,
Gode Ea fi dunu da bagahame galu. Ilia da Ga: ina: ne soge ganodini ga fi dunu agoane ba: i.
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè láti ìjọba kan sí èkejì.
Ilia da soge enoga enogaia udigili lafiadalu.
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú; nítorí tiwọn, ó bá àwọn ọba wí.
Be Gode da ili gaga: iba: le, eno fi da ili hame banenesi. Ili gaga: ma: ne, Gode da eno hina bagade dunu ilima amane sia: i,
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi; má ṣe pa àwọn wòlíì mi lára.”
“Na ilegei hawa: hamosu dunu, ilima mae se nabasima. Na balofede dunuma, mae digili ba: ma!”
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé; ẹ máa fi ìgbàlà rẹ̀ hàn láti ọjọ́ dé ọjọ́.
Hina Godema gesami hea: le hahawane nodone sia: ma! Osobo bagade fifi asi gala huluanema gesami hea: ma. Eso huluane Ea nini gaga: i sia: noga: idafa amo sia: nanoma.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ohun ìyàlẹ́nu tí ó ṣe láàrín gbogbo ènìyàn.
Fifi asi galama Ea hadigi amodili ima. E da fifi asi gala huluanema Ea gasa bagade hou amo hamonanebeba: le, ilima sisia: ma.
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ; òun ni kí a bẹ̀rù ju gbogbo àwọn Ọlọ́run lọ.
Hina Gode da bagadedafaba: le, Ema baligili nodomu da defea. Eno ‘gode’ da gudulisili, Ema fawane da baligili nodone dawa: mu da defea.
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà, ṣùgbọ́n Olúwa dá àwọn ọ̀run.
Eno ‘gode’ fifi asi gala amoga galebe da ogogole ‘gode’ fawane, be Hina Gode da mu huluane hahamoi.
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀; agbára àti ayọ̀ ni ó wà ní ibi ibùgbé rẹ̀.
Hadigi amola baligili gasa bagade da E sisiga: sa, gasa bagade amola noga: idafa ba: su da Ea Debolo Diasu amo nabale galei.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè, ẹ fi ògo àti ipá fún Olúwa.
Osobo bagade dunu huluane! Hina Godema nodone sia: ma! Ea gasa bagade hou amola Ea hadigidafa amoma nodone sia: ma!
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀; gbé ọrẹ kí ẹ sì wá síwájú rẹ̀. Sìn Olúwa nínú inú dídùn ìwà mímọ́ rẹ̀.
Hina Gode Ea hadigi Dio amoma nodone sia: ma. Ea Debolo Diasu ganodini Ema iasu gaguli misa. Hadigidafa Gode da amogawi doaga: sea, Ea midadi beguduma!
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé! Ayé sì fi ìdí múlẹ̀; a kò sì le è ṣí i.
Fifi asi gala huluane! Ema beda: iba: le, uguguma! Osobo bagade da noga: le ligisiba: le, fogomu gogolei.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn; lẹ́ kí wọn kí ó sọ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, pé “Olúwa jẹ ọba!”
Osobo bagade amola mu, ali nodoma! Fifi asi gala huluanema amane olelema, “Hina Gode da Hina Bagadedafa!”
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀; Jẹ́ kí àwọn pápá kí ó hó fún ayọ̀, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀!
Hano wayabo bagade amola amo ganodini esalebe liligi huluane! Huma! Amola soge, di ganodini liligi dialebe huluane nodone sia: ma!
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin, wọn yóò kọrin fún ayọ̀ níwájú Olúwa, nítorí tí ó wá láti ṣèdájọ́ ayé.
Hina Gode da osobo bagade ouligimusa: masea, ifalabo aligi da nodone sia: mu. E da defeledafa Ea moloidafa fofada: su amoga fifi asi huluane ouligimu.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára; ìfẹ́ ẹ rẹ̀ dúró títí láé.
Hina Godema nodoma! Hina Godema nodone sia: ma! Bai E da noga: idafa, amola Ea asigi hou da mae fisili dialumu.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa; kó wa jọ kí o sì gbà wá kúrò lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè, kí àwa kí ó lè fi ọpẹ́ fún orúkọ mímọ́ rẹ, kí àwa kí ó lè yọ̀ nínú ìyìn rẹ̀.”
Hina Godema amane sia: ma, “Hina Gode! Ninia Gode! Nini gaga: ma! Ninia da fifi asi gala amo ganodini esala, amoga nini Isala: ili sogega buhagimusa: oule misa. Amasea, ninia da Dia hadigi Dio amoma nodone sia: mu.”
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, láé àti láéláé. Lẹ́yìn náà gbogbo àwọn ènìyàn wí pé, “Àmín,” wọ́n “Yin Olúwa.”
Hina Godema nodoma! Isala: ili ilia Godema nodoma Wali amola eso huluane mae fisili, Ema nodone sia: nanoma! Amalalu, dunu huluane da “Ama” sia: ne, Hina Godema nodone sia: ne gadoi.
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
Da: ibidi da A: isa: fe amola Lifai fi dunu, amo Gode Ea Gousa: su Sema Gagili midadi, eso huluane hamobe nodone sia: ne gadosu hou, amo ouligima: ne, ilegei.
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
Da: ibidi da Oubede Idome (Yediudane egefe) amola ea fi dunu eno68agoane, amo dunu fidima: ne ilegei. Logo ga: su ouligisu dunu da Housa amola Oubede Idome.
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
Be gobele salasu dunu Sa: idoge amola ea gobele salasu fi dunu, ilia da Gibione moilai bai bagadega (nodone sia: ne gadosu sogebi eno) Hina Godema nodone sia: ne gadosu hou ouligisu.
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
Ilia da amo dunu hahabe amola daeya, sema amo da Hina Gode da Isala: ili dunuma i, amo defele, ohe gogo gobele salimusa: ilegei.
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
Ilia da amo dunu fidima: ne, amola Hina Gode Ea mae fisili asigidafa hou dawa: ma: ne, Ema nodone gesami hea: ma: ne, Hima: ne, Yediudane amola eno dunu, ilegei.
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
Hima: ne amola Yediudane amolawane da dalabede amola giga: mesa amola dusu liligi eno amoga ilia da nodone gesami hea: su fidisu, amo ouligi. Yediudane ea fi dunu da logo ga: su sosodo aligisu hou amo ouligi.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
Amalalu, dunu huluane da ilia diasua buhagi. Amola Da: ibidi da ea diasu, ea sosogo gilisili esalumusa: buhagi.

< 1 Chronicles 16 >