< 1 Chronicles 14 >
1 Nísinsin yìí Hiramu àti ọba Tire rán oníṣẹ́ sí Dafidi, àti pẹ̀lú igi kedari pẹ̀lú àwọn ọ̀mọ̀lé àti gbẹ́nàgbẹ́nà láti kọ́ ààfin fún un.
NO Hirama ke alii o Turo, hoouna mai la ia i na elele io Davida la, me na laau kedera, me na kalaipohaku a me na kamana, e hana lakou i hale nona.
2 Dafidi sì mọ Israẹli àti pé Olúwa ti fi òun ṣe ọba lórí Israẹli àti pé ìjọba rẹ̀ ga jùlọ nítorí ti àwọn ènìyàn rẹ̀.
A ike iho la o Davida, na Iehova ia i hoopaa i alii maluna o ka Iseraela, no ka mea, ua hookiekieia kona aupuni iluna, no kona poe kanaka, o ka Iseraela.
3 Ní Jerusalẹmu Dafidi mú ọ̀pọ̀ ìyàwó ó sì di baba àwọn ọmọ ọkùnrin púpọ̀ àti ọmọbìnrin.
Lawe ae la O Davida i na wahine hou ma Ierusalema: a na Davida mai na keikikane a me na kaikamahine hou.
4 Èyí ni orúkọ àwọn ọmọ náà tí wọ́n bí fún un níbẹ̀: Ṣammua, Ṣobabu, Natani, Solomoni,
Eia na inoa o na keiki i loaa ia ia ma Ierusalema; o Samua, o Sobaba, o Natana, a o Solomona,
5 Ibhari, Eliṣua, Elifeleti,
O Ibehara, o Elisua, o Elipeleta,
O Noga, o Nepega, o Iapia,
7 Eliṣama, Beeliada, àti Elifeleti.
O Elisama, o Beeliada, a o Elipeleta.
8 Nígbà tí àwọn ará Filistini gbọ́ pé a ti fi àmì òróró yàn Dafidi ní ọba lórí gbogbo Israẹli, wọ́n sì lọ sókè pẹ̀lú ipá láti wá a rí, ṣùgbọ́n Dafidi gbọ́ nípa rẹ̀ ó sì jáde lọ láti pàdé wọn.
A lohe ae la na Pilisetia, ua poniia o Davida i alii maluna o ka Iseraela a pau, pii mai la na Pilisetia a pau e imi ia Davida. A lohe aku la o Davida, a hele aku la ia a ku e ia lakou.
9 Nísinsin yìí àwọn ará Filistini ti wá láti gbógun ti àfonífojì Refaimu;
Hele mai la na Pilisetia, a hoomoana iho la ma ke awawa o Repaima.
10 Dafidi sì béèrè lọ́dọ̀ Ọlọ́run wí pé, “Kí èmi kí ó gòkè tọ àwọn ará Filistini lọ bí? Ìwọ ó ha fi wọ́n lé mi lọ́wọ́?” Olúwa sì wí fún un pé, “Gòkè lọ èmi ó sì fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́.”
Ninau aku la o Davida i ke Akua, i aku la, E pii aku anei au e ku e i na Pilisetia? E hoolilo anei hoi oe ia lakou i kuu lima? I mai la hoi o Iehova ia ia, E pii aku oe, no ka mea, e hoolilo aku no wau ia lakou i kou lima.
11 Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi àti àwọn ènìyàn rẹ̀ gòkè lọ sí Baali-Perasimu, níbẹ̀ ó sì kọlù wọ́n. Ó sí wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí omi tí ya jáde, Ọlọ́run ti ya Dafidi lórí àwọn ọ̀tá mi pẹ̀lú ọwọ́ mi.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń pè ibẹ̀ ní Baali-Perasimu.
Hele mai la lakou i Baala-perazima, a luku aku la o Davida ia lakou malaila. Alaila, i aku la o Davida, Ua poha aku la o Iehova maluna o ko'u poe enemi, e like me ka poha ana o ka wai. Nolaila, kapa aku la lakou i ka inoa o ia wahi, o Baala-perazima.
12 Àwọn ará Filistini sì ti fi àwọn òrìṣà wọn sílẹ̀ níbẹ̀. Dafidi sì pa á láṣẹ láti jó wọn nínú iná.
A haalele mai lakou i na kii akua o lakou ilaila, kauoha aku la o Davida, a ua puhiia lakou i ke ahi.
13 Lẹ́ẹ̀kan sí i àwọn ará Filistini gbógun wọ́n sì fọ́nká àfonífojì,
A hoomoana hou aku la na Pilisetia ma ke awawa.
14 Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi sì tún béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run, Ọlọ́run sì dalóhùn pé, “Má ṣe gòkè tààrà, ṣùgbọ́n ẹ yí wọn ká, kí ẹ sì mú wọn níwájú igi muliberi.
Nolaila, ninau hou aku la o Davida i ke Akua; a olelo mai la ke Akua ia ia, Mai pii aku oe mahope o lakou: e huli ae mai o lakou aku, a e hoi mai maluna o lakou la ma kahi e ku pono ana i na laau silika.
15 Tí ó bá sì ṣe, tí ẹ̀yin bá ti gbọ́ ìró ẹsẹ̀ ní orí òkè igi muliberi, ẹ jáde fún ogun, nítorí èyí yóò fihàn pé Ọlọ́run ti jáde níwájú rẹ láti kọlu àwọn ọmọ-ogun Filistini.”
Ala lohe oe i ka halulu o ka hele ana ma na welau o na laau silika, alaila e hele aku oe e hoouka i ke kaua: no ka mea, ua hala aku ke Akua imua ou e pepehi i ka poe kaua o na Pilisetia.
16 Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi ṣe ohun tí Ọlọ́run ti pàṣẹ fún wọn, wọ́n sì kọlu àwọn ọmọ-ogun Filistini láti gbogbo ọ̀nà Gibeoni lọ sí Geseri.
Nolaila, hana aku la o Davida e like me ka ke Akua i kauoha ai ia ia: a pepehi aku la lakou i na Pilisetia mai Gibeona aku a hiki i Gazera.
17 Bẹ́ẹ̀ ni òkìkí Dafidi tàn ká gbogbo ilẹ̀ káàkiri, Olúwa sì mú kí gbogbo orílẹ̀-èdè bẹ̀rù rẹ̀.
Kui aku la ka lono no Davida i na aina a Pau; a hookau aku la o Iehova i ka makau ia ia maluna o na lahuikanaka a pau.