< 1 Chronicles 13 >

1 Dafidi sì gbèrò pẹ̀lú olúkúlùkù àwọn ìjòyè rẹ̀, àwọn aláṣẹ ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn aláṣẹ ọgọ́rùn-ún
Hina bagade Da: ibidi da Isala: ili dadi gagui ouligisu dunu noga: i amo gilisimusa: bu wele sia: i. Ilia da dadi gagui dunu 1,000 agoane gilisi amola dunu 100 agoane gilisi amoga ouligisu dunu ba: i.
2 Dafidi sì wí fún gbogbo àwọn ìjọ Israẹli pé, tí ó bá dára lójú yín àti tí ó bá ṣe jẹ́ àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wa, jẹ́ kí a ránṣẹ́ sí ọ̀nà jíjìn àti gbígbòòrò sí àwọn arákùnrin wa tókù ní gbogbo àwọn agbègbè ìlú Israẹli àti pẹ̀lú àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi àwọn tí ó wà pẹ̀lú wọn nínú ìlú wọn àti pápá oko tútù, láti wá kó ara wọn jọ pọ̀ sọ́dọ̀ wa.
Amalalu, e da Isala: li dunu huluane ilima amane sia: i, “Dilia da defea sia: sea, amola ninia Hina Gode da agoane hanai galea, ninia da dunu huluane amola gobele salasu dunu amola Lifai fi dunu amo guiguda: nini gilisimusa: misa: ne sia: simu.
3 Ẹ jẹ́ kí a gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa padà sọ́dọ̀ wa, nítorí wí pé àwa kò ṣe ìwádìí nípa rẹ̀ ní àsìkò ìjọba Saulu.
Amasea, ninia da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili lala masunu. (Solo ea ouligibi esoga ilia da Sema Gagili bu gaguli misunu hame dawa: digi).”
4 Gbogbo ìjọ náà sì gbà láti ṣe èyí nítorí ó dàbí wí pé ó tọ lójú gbogbo àwọn ènìyàn.
Dunu huluane da Da: ibidi ea sia: hahawane nabi.
5 Nígbà náà ni Dafidi pe gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ, láti ọ̀dọ̀ Ṣihori ní Ejibiti lọ sí Lebo ní ọ̀nà à bá wọ Hamati, láti gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run padà láti Kiriati-Jearimu.
Amaiba: le, Da: ibidi da Isala: ili dunu huluane gilisi. Ilia da soge amo da ga (south) Idibidi alaloa, asili Ha: ima: de adobo gigadofa ahoasu ga (north) diala, amo soge huluanega, Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amo Gilia: de Yialimi moilaiga lale, Yelusalemega gaguli masa: ne, misi.
6 Dafidi àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli pẹ̀lú rẹ̀ lọ sí Baalahi ti Juda (Kiriati-Jearimu) láti gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run Olúwa tí a fi orúkọ rẹ̀ pè, tí ó jókòó láàrín kérúbù gòkè wá.
Da: ibidi amola Isala: ili dunu huluane da Ba: ila moilai, Yuda soge ganodini, amoga asi. Ilia da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili (amoga da Hina Gode Bagadedafa Ea Dio gala. Ea Fisu da ‘selabimi’ amoga gadodili ba: sa, ) amo bu gaguli misa: ne asi.
7 Wọ́n sì gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run láti ilé Abinadabu lórí kẹ̀kẹ́ tuntun, Ussa àti Ahio ń ṣọ́ ọ.
Ilia da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amo Abinada: be ea diasu agolo da: iya galu amoga lale, gaguli fula ahoasu gaheabolo bulamagauga hiougima: ne, amo da: iya ligisi. Asa amola Ahaiou (Abinada: be egefela) da amo gaguli fula ahoasu ea ahoabe amo adonana ahoanu.
8 Dafidi àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ni wọ́n ṣe àjọyọ̀ pẹ̀lú gbogbo agbára wọn níwájú Ọlọ́run, pẹ̀lú orin àti pẹ̀lú dùùrù, ohun èlò orin olókùn, tambori, kimbali pẹ̀lú ìpè.
Da: ibidi amola Isala: ili dunu huluane da Hina Gode Ea nodoma: ne, gogosa: amola gesami hea: sa ahoanebe ba: i. Ilia da sani baidama, ilibu, giga: mesa, amola dalabede amo dudududaha ahoasu.
9 Nígbà tí wọ́n dé sí ilẹ̀ ìpakà Kidoni, Ussa sì na ọwọ́ rẹ̀ síta láti di àpótí ẹ̀rí Olúwa mú, nítorí màlúù kọsẹ̀.
Ilia da Siaidone widi dadibisu sogebi doaga: loba, bulamagau da didigaboi. Asa da ea lobo ligiagale, Gousa: su Sema Gagili mae sa: ima: ne banene gagui.
10 Ìbínú Olúwa, sì ru sí Ussa, ó sì lù ú bolẹ̀ nítorí o ti fi ọwọ́ rẹ̀ lórí àpótí ẹ̀rí. Bẹ́ẹ̀ ni ó sì kú síbẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
Amogaluwane hedolo, Hina Gode da Asama ougi. E da Asa fane legei. Bai e da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amo mae beda: ga digili ba: i. Asa da amogawi Gousa: su Sema Gagili dafulili, Gode Ea midadi bogoi dagoi.
11 Nígbà náà Dafidi sì bínú nítorí ìbínú Olúwa ké jáde lórí Ussa, àti títí di òní, wọ́n sì ń pe ibẹ̀ ní Peresi-Usa.
Amaiba: le, amogainini amo sogebi ea dio da ‘Bilese Asa’ dialu. (Amo ea dawa: loma: ne da “Asa ea se Iasu”). Hina Gode da ougili Asa medole legeiba: le, Da: ibidi amola da ougi bagade ba: i.
12 Dafidi sì bẹ̀rù Ọlọ́run ní ọjọ́ náà, ó sì béèrè pé, báwo ni èmi náà ó ṣe gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run sí ọ̀dọ̀ mi?
Amalalu, Da: ibidi da Hina Godeba: le beda: i galu. E da amane sia: i, “Na da habodane Gousa: su Sema Gagili amo bu gaguli masa: bela: ?”
13 Kò gbé àpótí ẹ̀rí náà wá sí ọ̀dọ̀ ará rẹ̀ ní ìlú ti Dafidi dípò èyí, ó sì gbé e yà sí ilé Obedi-Edomu ará Gitti.
Amaiba: le, e da amo Yelusaleme moilai bai bagadega hame gaguli masunu dawa: i. E da logo yolesili, dunu ea dio amo Oubede Idome (Ga: de moilai dunu) amo ea diasuga Gousa: su Sema Gagili gaguli asi.
14 Àpótí ẹ̀rí Olúwa sì wà lọ́dọ̀ àwọn ará ilé Obedi-Edomu ní ilé rẹ̀ fún oṣù mẹ́ta, Olúwa sì bùkún agbo ilé àti gbogbo ohun tí ó ní.
Gousa: su Sema Gagili amo da amogawi oubi udiana dialu. Amola Hina Gode da Oubede Idome amola ea sosogo fi ilima hahawane dogolegele hamoi.

< 1 Chronicles 13 >