< 1 Chronicles 12 >

1 Àwọn wọ̀nyí ni ọkùnrin tí ó wá sí ọ̀dọ̀ Dafidi ní Siklagi, nígbà tí ó sá kúrò níwájú Saulu ọmọ Kiṣi (wọ́n wà lára àwọn jagunjagun ẹni tí ó ràn án lọ́wọ́ láti ibi ìjà.
Ko te hunga tenei i haere ki a Rawiri ki Tikiraka, i a ia ano e putiki tonu ana i roto i te pa i te wehi o Haora tama a Kihi: no nga marohirohi ratou, hei tuara mona ki te whawhai.
2 Wọ́n sì mú wọn pẹ̀lú ìtẹríba wọ́n sì lágbára láti ta ọfà tàbí láti ta kànnàkànnà òkúta ní ọwọ́ òsì tàbí ní ọwọ́ ọ̀tún, wọ́n sì jẹ́ ìbátan ọkùnrin Saulu láti ẹ̀yà Benjamini):
He hunga kukume kopere ratou, ko te maui, ko te matau, ki te kotaha kohatu, ki te kopere i te pere; no nga teina ano o Haora, no Pineamine.
3 Ahieseri olórí wọn àti Joaṣi àwọn ọmọ Ṣemaah ará Gibeah: Jeṣieli àti Peleti ọmọ Asmafeti, Beraka, Jehu ará Anatoti.
Ko Ahietere te upoko, na ko Ioaha, he tama raua na Hemaa Kipeati; ko Ietiere, ko Perete he tama na Atamawete; ko Peraka, ko Iehu Anatoti;
4 Àti Iṣmaiah ará Gibeoni, ọkùnrin alágbára kan lára àwọn ọgbọ̀n ẹni tí ó jẹ́ olórí nínú àwọn ọgbọ̀n; Jeremiah, Jahasieli, Johanani, Josabadi ará Gedera,
Ko Ihimaia Kipeoni, he marohirohi ia i roto i te toru tekau, he rangatira ano no te toru tekau; ko Heremaia, ko Tahatiere, ko Iohanana, ko Iohapara Kererati;
5 Elusai, Jerimoti, Bealiah, Ṣemariah àti Ṣefatia ará Harufiti;
Ko Erutai, ko Terimoto, ko Pearia, ko Hemaria, ko Hepatia Harupi;
6 Elkana, Iṣiah, Asareeli, Joeseri àti Jaṣobeamu ará Kora;
Ko Erekana, ko Ihiia, ko Atareere, ko Toetere, ko Iahopeama, he Korahi ratou;
7 àti Joẹla, àti Sebadiah àwọn ọmọ Jerohamu láti Gedori.
Ko Toera, ko Teparia, he tama na Ierohama o Keroro.
8 Díẹ̀ lára àwọn ará Gadi yà sọ́dọ̀ Dafidi ní ibi gíga ní aginjù. Wọ́n sì jẹ́ onígboyà ológun tí ó múra fún ogun tí ó sì lágbára láti di asà àti ẹṣin mú. Ojú wọn sì dàbí ojú kìnnìún, wọ́n sì yára bí àgbọ̀nrín lórí àwọn òkè.
Na o nga Kari i maunu etahi ki a Rawiri ki te pourewa i te koraha, he tangata marohirohi, i rauhangatia mo te whawhai, he hunga hapai i te whakangungu rakau, i te tao: ko o ratou mata me te mea he kanohi raiona, rite tonu o ratou tere ki to nga a naterope i runga i nga maunga;
9 Eseri sì jẹ́ ìjòyè, Obadiah sì jẹ́ igbákejì akọgun, Eliabu ẹlẹ́ẹ̀kẹta,
Ko Etere te upoko, ko Oparia te tuarua, ko Eriapa te tuatoru;
10 Miṣimana ẹlẹ́ẹ̀kẹrin, Jeremiah ẹlẹ́ẹ̀karùnún
Ko Mihimana te tuawha, ko Heremaia te tuarina;
11 Attai ẹlẹ́ẹ̀kẹfà, Elieli èkeje,
Ko Atai te tuaono, ko Eriere te tuawhitu;
12 Johanani ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ Elsabadi ẹlẹ́ẹ̀kẹsàn-án
Ko Iohanana te tuawaru, ko Eretapara te tuaiwa;
13 Jeremiah ẹlẹ́ẹ̀kẹwàá àti Makbannai ẹlẹ́ẹ̀kọkànlá.
Ko Heremaia te tuatekau, ko Makapanai te tekau ma tahi.
14 Àwọn ará Gadi wọ́n sì jẹ́ olórí ogun; ẹni tí ó kéré jù sì jẹ́ àpapọ̀ ọgọ́rùn-ún, àti fún ẹni tí ó pọ̀jù fún ẹgbẹ̀rún.
Ko enei o nga tama a Kara he rangatira ope: ko te mea iti rawa hei rangatira mo te rau, a ko te mea nui rawa hei rangatira mo te mano.
15 Àwọn ni ẹni tí ó rékọjá Jordani ní oṣù àkọ́kọ́ nígbà tí ó kún bo gbogbo bèbè rẹ̀, wọ́n sì lé gbogbo àwọn tí ó ń gbé nínú àfonífojì, lọ sí ìlà-oòrùn àti níhà ìwọ̀-oòrùn.
Ko te hunga tenei i whiti nei i Horano i te marama tuatahi, i te mea kua ngawha ki runga i ona pareparenga katoa; a whati ana i a ratou te hunga katoa o nga raorao whaka te rawhiti, a whaka te hauauru.
16 Ìyókù ará Benjamini àti àwọn díẹ̀ ọkùnrin láti Juda lọ sí ọ̀dọ̀ Dafidi ní ibi gíga.
I haere mai ano etahi o nga tama a Pineamine me etahi o a Hura ki te pourewa ki a Rawiri.
17 Dafidi sì lọ láti lọ pàdé wọn ó sì wí fún wọn pé, “Tí ẹ bá wá sọ́dọ̀ mi lálàáfíà, láti ràn mí lọ́wọ́ mo ṣetán láti mú un yín wà ní ìṣọ̀kan pẹ̀lú mi ṣùgbọ́n tí ẹ bá wá láti dá mi sí fún àwọn ọ̀tá mi nígbà tí ọwọ́ mi bá mọ́ kúrò nínú ìwà agbára, kí Ọlọ́run àwọn baba wa kí ó sì ri kí ó sì ṣe ìdájọ́.”
Na ka puta a Rawiri ki te whakatau i a ratou, a ka oho, ka mea ki a ratou, Ki te mea he haere pai mai ta koutou ki ahau, he whakauru, ka kotahi tonu o tatou ngakau. Tena ki te tinihanga, te tuku i ahau ki oku hoariri, i te mea kahore nei he tutu a oku ringa, ma te Atua o o tatou matua e titiro mai, e riri.
18 Nígbà náà Ẹ̀mí Mímọ́ wa sórí Amasai ìjòyè àwọn ọgbọ̀n, ó sì wí pé, “Tìrẹ ni àwa ń ṣe, ìwọ Dafidi! Àwa pẹ̀lú rẹ, ìwọ ọmọ Jese! Àlàáfíà, àlàáfíà fún ọ, àti àlàáfíà fún àwọn tí ó ràn ó lọ́wọ́, nítorí Ọlọ́run rẹ̀ yóò ràn ọ́ lọ́wọ́.” Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi sì gbà wọ́n ó sì mú wọn jẹ olórí ẹgbẹ́ ogun.
Na kua tau te wairua ki a Amahai, ko ia nei te rangatira o te toru tekau, a ka ki ia, Kei a koe matou, e Rawiri, hei hoa mou, e te tama a Hehe, Kia mau, kia mau te rongo ki a koe; kia mau ano ki ou whakauru; ko tou Atua hoki hei whakauru mou. Na kua riro ratou i a Rawiri, a meinga ana ratou e ia hei rangatira rangapu.
19 Díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin Manase sì yà sí ọ̀dọ̀ Dafidi nígbà tí ó lọ pẹ̀lú àwọn ará Filistini láti bá Saulu jà. (Òun àti àwọn ọkùnrin rẹ̀ wọn kò sì ran ará Filistini lọ́wọ́ nítorí, lẹ́yìn tiwọn sọ̀rọ̀ papọ̀, àwọn olórí wọn rán wọn jáde, wọ́n sì wí pé, “Yóò jẹ́ ìparun fún wa tí ó bá padà tọ ọ̀gá rẹ̀ Saulu lọ.”)
Na o Manahi hoki i papahoro etahi ki a Rawiri, i a ia i haere tahi ai me nga Pirihitini ki te whawhai ki a Haora, otiia kihai ratou i uru ki a ratou: i panaia hoki ia e nga rangatira o nga Pirihitini, he mea, whakaaro ano e ratou, i mea ratou, T era ia e taka atu ki tona ariki, ki a Haora, ko o tatou upoko e raru.
20 Nígbà tí Dafidi lọ sí Siklagi, àwọn wọ̀nyí ni ọkùnrin ti Manase ẹni tí ó sì yà sọ́dọ̀ rẹ̀. Adina, Josabadi, Jediaeli, Mikaeli, Josabadi, Elihu àti Siletai, àwọn olórí ìrẹ́pọ̀ ti ẹgbẹẹgbẹ̀rún ní Manase.
I a ia e haere ana ki Tikiraka, ka papahoro mai ki a ia o Manahi ko Arana, ko Iotapara, ko Teriaere, ko Mikaera, ko Iotapara, ko Erihu, ko Tiritai, he rangatira no nga mano o Manahi.
21 Wọ́n sì ran Dafidi lọ́wọ́ lórí ẹgbẹ́ ogun náà, nítorí gbogbo wọn ni akọni ènìyàn àwọn sì tún ni olórí nínú àwọn ọmọ-ogun rẹ̀.
Ko ratou nga whakauru mo Rawiri ki te whawhai ki nga torohe; he marohirohi hoki, he toa, ratou katoa, he rangatira ope.
22 Ọjọ́ dé ọjọ́ ni àwọn ọkùnrin wá láti ran Dafidi lọ́wọ́, títí tí ó fi ní àwọn ológun ńlá, bí ogun Ọlọ́run.
I haere hoki ratou i taua wa ki a Rawiri i tena ra, i tena ra, hei whakauru mona, no kua nui te ope, ano he ope na te Atua.
23 Àwọn wọ̀nyí sì ni iye ọkùnrin tí ó ti di ìhámọ́ra fún ogun àwọn ẹni tí ó wá sọ́dọ̀ Dafidi ní Hebroni láti yí ìjọba Dafidi padà sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ.
Ko te tokomaha tenei o nga rangatira, he hunga i rite rawa mo te whawhai, i haere ki a Rawiri ki Heperona hei whakariro i te kingitanga o Haora ki a ia; kia rite ai ki ta Ihowa kupu.
24 Ọkùnrin Juda, tí o ń gbé asà àti ọ̀kọ̀, ẹgbàáta lé lẹ́gbẹ̀rin tí ó ti di ìhámọ́ra fún ogun.
Ko nga tama a Hura, he hunga hapai i te whakangungu rakau, i te tao e ono mano e waru rau, rite rawa i te patu mo te whawhai.
25 Àwọn ọkùnrin Simeoni, akọni tó mú fún ogun sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin ó lé ọgọ́rùn-ún;
O nga tama a Himiona, he marohirohi, he toa mo te whawhai, e whitu mano kotahi rau.
26 àwọn ọkùnrin Lefi ẹgbàajì ó le ẹgbẹ̀ta,
O nga tama a Riwai e wha mano e ono rau.
27 pẹ̀lú Jehoiada, olórí ìdílé Aaroni pẹ̀lú ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ènìyàn,
Na ko Iehoiara te rangatira o te whare o Arona, a e toru mano e whitu rau ona hoa;
28 àti Sadoku akọni ọ̀dọ́mọkùnrin, pẹ̀lú àwọn méjìlélógún ìjòyè láti ọ̀dọ̀ àwọn ìdílé rẹ̀;
Me Haroko ano, he taitama marohirohi, he toa, ratou ko te whare o tona papa, e rua tekau ma rua nga rangatira.
29 àwọn arákùnrin Benjamini ìbátan ọkùnrin Saulu ẹgbẹ̀rún mẹ́ta, ọ̀pọ̀ nínú àwọn ẹni tí ó si kù ní olóòtítọ́ sí ilé Saulu títí di ìgbà náà;
A, o nga tama a Pineamine, o nga teina o Haora, e toru mano: ko to ratou nuinga hoki i mau tonu ki te whare o Haora a taea noatia taua ra.
30 àwọn arákùnrin Efraimu, ògbójú akọni, ènìyàn Ọlọ́run ni wọ́n nílé baba wọn ogún ẹgbẹ̀rún ó le ẹgbẹ̀rin;
Na o nga tama a Eparaima, e rua tekau mano e waru rau, he marohirohi, he toa, he hunga whai ingoa i roto i nga whare o o ratou matua.
31 àwọn ọkùnrin nínú ààbọ̀ ẹ̀yà Manase, tí a yàn nípa orúkọ láti wá àti láti yan Dafidi gẹ́gẹ́ bí ọba, ẹgbàá mẹ́sàn.
A, o tetahi tanga o te iwi o Manahi, kotahi tekau ma waru mano, he mea whakahua o ratou ingoa, hei haere ki te whakakingi i a Rawiri.
32 Àti ní ti àwọn ọmọ Isakari, àwọn ẹni tí ó ní òye àkókò, láti mọ ohun tí Israẹli ìbá máa ṣe; olórí wọn jẹ́ ìgbà; àti gbogbo àwọn ìbátan wọn ń bẹ ní ìkáwọ́ wọn.
Na, o nga tama a Ihakara, he hunga mohio ki nga wa, i mohio ai ki nga mahi ma Iharaira; e rua rau o ratou ariki; kei o enei mangai ano he tikanga mo o ratou teina.
33 Àwọn ọkùnrin Sebuluni, àti àwọn jagunjagun tí ó ti nípa ogun múra fún ogun pẹ̀lú oríṣìíríṣìí ohun èlò ìjà, láti ran Dafidi lọ́wọ́ pẹ̀lú àwọn tí kò fi iyèméjì ṣe ìjólóòótọ́ wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n.
O Hepurona, ko te hunga e ahei te haere ki te whawhai, he mohio ki te tatai i te riri, e mau ana i nga mea katoa mo te whawhai, e rima tekau mano; he hunga e taea te whakatika te tatai o te riri, a kahore o ratou ngakau rua.
34 Àwọn ọkùnrin Naftali, ẹgbẹ̀rún ìjòyè àpapọ̀ pẹ̀lú ẹgbàá méjìdínlógún. Ọkùnrin tí wọ́n gbé asà àti ọ̀kọ̀ wọn.
A o Napatari kotahi mano nga rangatira, e toru tekau ma whitu mano o ratou hoa, rite rawa i te whakangungu rakau, i te tao.
35 Àwọn ọkùnrin Dani, tí wọ́n ṣetán fún ogun ẹgbàá mẹ́tàlá.
Na, o nga Rani, he hunga mohio ki te tatu, e rua tekau ma waru mano e ono rau.
36 Àwọn ọkùnrin Aṣeri, àwọn tí ó ti ní ìmọ̀ ogun múra fún ogun ọ̀kẹ́ méjì.
O Ahera, he hunga haere ki te whawhai, he mohio ki te tatau, e wha tekau mano.
37 Láti ìlà-oòrùn Jordani, ọkùnrin Reubeni, Gadi, àti ìdajì ẹ̀yà Manase, dìmọ́ra pẹ̀lú gbogbo onírúurú ohun èlò ìjà ọ̀kẹ́ mẹ́fà.
Na, o tera taha o Horano, o nga Reupeni, o nga Kari, o tetahi tanga o te hapu o Manahi, e mau ana i nga mea whawhai katoa mo te tatau, kotahi rau e rua tekau mano.
38 Gbogbo èyí ni àwọn ọkùnrin ológun tí ó fi ara wọn fún ogun láti ṣe iṣẹ́ fún nínú ẹgbẹ́. Wọ́n wá sí Hebroni tí ó kún fún ìpinnu láti fi Dafidi jẹ́ ọba lórí gbogbo Israẹli. Gbogbo àwọn ìyókù lára àwọn ọmọ Israẹli sì jẹ́ onínú kan láti fi Dafidi jẹ ọba.
Ko enei, he tangata whawhai katoa, he mohio ki te tatau, he tapatahi tonu te ngakau i haere ai ki Heperona ki te mea i a Rawiri hei kingi mo Iharaira katoa. Na, ko era atu katoa o Iharaira, kotahi tonu te ngakau mo te whakakingi i a Rawiri.
39 Àwọn ọkùnrin náà lo ọjọ́ mẹ́ta níbẹ̀ pẹ̀lú Dafidi, wọ́n jẹ, wọ́n sì ń mu, nítorí ìdílé wọn ti pèsè oúnjẹ fún wọn.
A i reira ratou i a Rawiri, e toru nga ra e kai ana, e inu ana: he mea taka hoki na o ratou tuakana, teina.
40 Àwọn aládùúgbò láti ọ̀nà jíjìn gẹ́gẹ́ bí Isakari, Sebuluni àti Naftali gbé oúnjẹ wá lórí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, lórí ràkunmí, àti lórí ìbáaka àti lórí màlúù, àní oúnjẹ ti ìyẹ̀fun, èso àjàrà gbígbẹ, èso ọ̀pọ̀tọ́, àkàrà dídùn, ọtí wáìnì, òróró, màlúù àti àgùntàn, nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ayọ̀ wà ní Israẹli.
Na, ko te hunga tata ki a ratou, tae noa atu ki a Ihakara, ki a Hepurona, ki a Napatari, i kawe taro mai i runga i nga kaihe, i nga kamera, i nga muera, a i nga kau, he kai, he paraoa, he papa piki, he tautau karepe, he waina, he hinu, he kau, h e hipi, tona tini; he koa hoki no Iharaira.

< 1 Chronicles 12 >