< 1 Chronicles 1 >

1 Adamu, Seti, Enoṣi,
Adán, Set, Enós,
2 Kenani, Mahalaleli, Jaredi,
Quenán, Malalel, Jared,
3 Enoku, Metusela, Lameki, Noa.
Enoc, Matusalén, Lamec, Noé.
4 Àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
Los hijos de Noé: Sem, Cam, y Jafet.
5 Àwọn ọmọ Jafeti ni: Gomeri, Magogu, Madai; Jafani, Tubali, Meṣeki àti Tirasi.
Los hijos de Jafet: Gómer, Magog, Madai, Javan, Tubal, Mésec, and Tirás.
6 Àwọn ọmọ Gomeri ni: Aṣkenasi, Rifati àti Togarma.
Los hijos de Gomer: Asquenaz, Rifat, y Togarma.
7 Àwọn ọmọ Jafani ni: Eliṣa, Tarṣiṣi, Kittimu, àti Dodanimu.
Los hijos de Javán: Elisá, Tarsis, Quitín, Rodanín.
8 Àwọn ọmọ Hamu ni: Kuṣi, Ejibiti, Puti, àti Kenaani.
Los hijos de Cam: Cus, Mizrayin, Fut, y Canaán.
9 Àwọn ọmọ Kuṣi ni: Seba, Hafila, Sabta, Raama, àti Sabteka. Àwọn ọmọ Raama: Ṣeba àti Dedani.
Los hijos de Cus: Seba, Javilá, Sabta, Ragama y Sabteca. Los hijos de Ragama: Sabá y Dedán.
10 Kuṣi sì bí Nimrodu ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
Cus fue el padre de Nimrod, que se convirtió en el primer tirano del mundo.
11 Ejibiti sì bí Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Naftuhimu,
Mizrayin fue el padre de los ludeos, anameos, leabitas, naftuitas,
12 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
patruseos, caslujitas y los caftoritas (quienes eran antepasados de los filisteos).
13 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀, àti Heti,
Canaán fue el padre Sidón, su primogénito, y de los hititas,
14 àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
jebuseos, amorreos, gergeseos,
15 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
heveos, araceos, sineos,
16 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
arvadeos, zemareos y jamatitas.
17 Àwọn ọmọ Ṣemu ni: Elamu, Aṣuri, Arfakṣadi, Ludi àti Aramu. Àwọn ọmọ Aramu: Usi, Huli, Geteri, àti Meṣeki.
Los hijos de Sem: Elam, Asur, Arfaxad, Lud y Harán. Los hijos de Harán: Uz, Hul, Guéter, y Mésec.
18 Arfakṣadi sì bí Ṣela, Ṣela sì bí Eberi.
Arfaxad fue el padre de Selá, y Selá el padre de Éber.
19 Eberi sì bí ọmọ méjì: ọ̀kan ń jẹ́ Pelegi, nítorí ní ìgbà ọjọ́ rẹ̀ ni ilẹ̀ ya; orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Joktani.
Éber tuvo dos hijos. Uno se llamaba Peleg, porque en su tiempo la tierra fue dividida; el nombre de su hermano fue Joctán.
20 Joktani sì bí Almodadi, Ṣelefi, Hasarmafeti, Jera.
Joctán fue el padre de Almodad, Sélef, Jazar Mávet, Yeraj,
21 Hadoramu, Usali, Dikla,
Adoram, Uzal, Diclá,
22 Ebali, Abimaeli, Ṣeba.
Obal, Abimael, Sabá,
23 Ofiri, Hafila, àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
Ofir, Javilá y Jobab. Todos estos fueron hijos de Joctán.
24 Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,
Sem, Arfaxad, Selá,
25 Eberi, Pelegi. Reu,
Éber, Peleg, Reú,
26 Serugu, Nahori, Tẹra,
Serug, Nacor, Téraj,
27 àti Abramu (tí ń ṣe Abrahamu).
y Abram (también llamado Abraham).
28 Àwọn ọmọ Abrahamu: Isaaki àti Iṣmaeli.
Los hijos de Abraham: Isaac e Ismael.
29 Èyí ni àwọn ọmọ náà: Nebaioti àkọ́bí Iṣmaeli: Kedari, Adbeeli, Mibsamu,
Estos fueron sus descendientes: Nebayot, quien fue el hijo primogénito de Ismael, Cedar, Adbeel, Mibsam,
30 Miṣima, Duma, Massa, Hadadi, Tema,
Mismá, Dumá, Masá, Hadad, Temá,
31 Jeturi, Nafiṣi, àti Kedema. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Iṣmaeli.
Jetur, Nafis y Cedema. Estos fueron los hijos de Ismael.
32 Àwọn ọmọ Ketura, obìnrin Abrahamu: Simrani, Jokṣani Medani, Midiani Iṣbaki àti Ṣua. Àwọn ọmọ Jokṣani: Ṣeba àti Dedani.
Los hijos que le nacieron a Cetura, la concubina de Abraham. Ella dio a luz a: Zimrán, Jocsán, Medán, Madián, Isbac y Súah. Los hijos de Jocsán: Sabá y Dedán.
33 Àwọn ọmọ Midiani: Efani, Eferi, Hanoku, Abida àti Eldaa. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Ketura.
Los hijos de Madián: Efá, Éfer, Janoc, Abidá y Eldá. Todos ellos fueron descendientes de Cetura.
34 Abrahamu sì jẹ́ baba Isaaki. Àwọn ọmọ Isaaki: Esau àti Israẹli.
Abraham fue el padre de Isaac. Los hijos de Isaac fueron Esaú e Israel.
35 Àwọn ọmọ Esau: Elifasi, Reueli, Jeuṣi, Jalamu, àti Kora.
Los hijos de Esaú: Elifaz, Reuel, Jeús, Jalán y Coré.
36 Àwọn ọmọ Elifasi: Temani, Omari, Sefi, Gatamu àti Kenasi; láti Timna: Amaleki.
Los hijos de Elifaz: Temán, Omar, Zefo, Gatán y Quenaz; además Amalec por medio de Timná.
37 Àwọn ọmọ Reueli: Nahati, Sera, Ṣamma àti Missa.
Los hijos de Reuel: Najat, Zera, Sama y Mizá.
38 Àwọn ọmọ Seiri: Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana, Diṣoni, Eseri àti Diṣani.
Los hijos de Seír: Lotán, Sobal, Zibeón, Aná, Disón, Ezer y Disán.
39 Àwọn ọmọ Lotani: Hori àti Homamu: Timna sì ni arábìnrin Lotani.
Los hijos de Lotán: Horí y Homán. La hermana de Lotán era Timná.
40 Àwọn ọmọ Ṣobali: Afiani, Manahati, Ebali, Ṣefo àti Onamu. Àwọn ọmọ Sibeoni: Aiah àti Ana.
Los hijos de Sobal: Alván, Manajat, Ebal, Sefó y Onam. Los hijos de Zibeón: Aja y Aná.
41 Àwọn ọmọ Ana: Diṣoni. Àwọn ọmọ Diṣoni: Hemdani, Eṣbani, Itrani, àti Kerani.
El hijo de Aná fue Disón. Los hijos de Dishón fueron Hemdán, Esbán, Itrán y Querán.
42 Àwọn ọmọ Eseri: Bilhani, Saafani àti Akani. Àwọn ọmọ Diṣani: Usi àti Arani.
Los hijos de Ezer: Bilán, Zaván y Acán. Los hijos de Disán: Uz y Arán.
43 Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu, kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli: Bela ọmọ Beori, orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.
Estos fueron los reyes que reinaron sobre Edom antes de que cualquier rey israelita reinara sobre ellos: Bela hijo de Beor, cuya ciudad se llamaba Dinaba.
44 Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Cuando murió Bela, Jobab hijo de Zera, proveniente de Bosra, asumió el reinado.
45 Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Tras la muerte de Jobab, Husam asumió el reinado entonces, y era proveniente de la tierra de los Temanitas.
46 Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.
Cuando murió Husam, Hadad, hijo de Bedad, asumió el reinado. Él fue quien derrotó a Madián en el país de Moab. El nombre de su ciudad era Avit.
47 Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Cuando murió Hadad, Samá, de Masreca, asumió el reinado.
48 Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Cuando murió Samá, Saúl, proveniente de Rehobot del río asumió el reinado.
49 Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani, ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Cuando murió Saúl, Baal-Hanán, hijo de Acbor, asumió el reinado.
50 Nígbà tí Baali-Hanani kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.
Cuando Baal-Hanán murió, Hadad reinó en su lugar. El nombre de su ciudad era Pau. El nombre de su esposa era Mehetabel, hija de Matred, nieta de Me-Zahab.
51 Hadadi sì kú pẹ̀lú. Àwọn baálẹ̀ Edomu ni: baálẹ̀ Timna, baálẹ̀ Alfa, baálẹ̀ Jeteti
Entonces murió Hadad. Los jefes de Edom eran: Timná, Alva, Jetet,
52 baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni.
Aholibama, Ela, Pinón,
53 Baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,
Quenaz, Temán, Mibzar,
54 Magdieli àti Iramu. Àwọn wọ̀nyí ni baálẹ̀ Edomu.
Magdiel, e Iram. Estos eran los jefes de Edom.

< 1 Chronicles 1 >