< 1 Chronicles 1 >

1 Adamu, Seti, Enoṣi,
Adam, Set, Enos.
2 Kenani, Mahalaleli, Jaredi,
Kienan, Mahalaleel, Jared.
3 Enoku, Metusela, Lameki, Noa.
Eonch, Matusalem, Lamech.
4 Àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
Noe, Sem, Cham, i Jafet.
5 Àwọn ọmọ Jafeti ni: Gomeri, Magogu, Madai; Jafani, Tubali, Meṣeki àti Tirasi.
Synowie Jafetowi: Gomer, i Magog, i Madaj, i Jawan, i Tubal, i Mesech, i Tyras,
6 Àwọn ọmọ Gomeri ni: Aṣkenasi, Rifati àti Togarma.
A synowie Gomerowi: Aschenaz, i Ryfat, i Togorma.
7 Àwọn ọmọ Jafani ni: Eliṣa, Tarṣiṣi, Kittimu, àti Dodanimu.
Synowie też Jawanowi: Elisa, i Tarsys, Cytym, i Dodanin.
8 Àwọn ọmọ Hamu ni: Kuṣi, Ejibiti, Puti, àti Kenaani.
Synowie Chamowi: Chus i Misraim, Put i Chanaan.
9 Àwọn ọmọ Kuṣi ni: Seba, Hafila, Sabta, Raama, àti Sabteka. Àwọn ọmọ Raama: Ṣeba àti Dedani.
A synowie Chusowi: Seba, i Hewila, i Sabta, i Regma, i Sabtacha; a synowie Regmy: Seba i Dedan.
10 Kuṣi sì bí Nimrodu ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
Spłodził też Chus Neroda; ten począł być możnym na ziemi.
11 Ejibiti sì bí Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Naftuhimu,
Misraim też spłodził Ludyma, i Hananima, i Laubima, i Naftuhyma,
12 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
I Patrusyma, i Chasłuchyma, (z których poszli Filistynowie) i Kaftoryma.
13 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀, àti Heti,
Potem Chanaan spłodził Sydona, pierworodnego swego, i Hetejczyka.
14 àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
I Jebuzejczyka, i Amorejczyka, i Giergiezejczyka,
15 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
I Hewejczyka, i Archajczyka, i Symejczyka,
16 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
I Aradejczyka, i Samarejczyka, i Chamatejczyka.
17 Àwọn ọmọ Ṣemu ni: Elamu, Aṣuri, Arfakṣadi, Ludi àti Aramu. Àwọn ọmọ Aramu: Usi, Huli, Geteri, àti Meṣeki.
Synowie Semowi: Elam, i Assur, i Arfachsad, i Lud, i Aram, i Chus, i Hul, i Gieter, i Mesech.
18 Arfakṣadi sì bí Ṣela, Ṣela sì bí Eberi.
A Arfachsad spłodził Selecha, a Selech spłodził Hebera.
19 Eberi sì bí ọmọ méjì: ọ̀kan ń jẹ́ Pelegi, nítorí ní ìgbà ọjọ́ rẹ̀ ni ilẹ̀ ya; orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Joktani.
A Heberowi urodzili się dwaj synowie, z których jednemu imię było Faleg, przeto, że za jego czasów rozdzielona jest ziemia; a imię brata jego Jektan.
20 Joktani sì bí Almodadi, Ṣelefi, Hasarmafeti, Jera.
A Jektan spłodził Elmodada, i Salefa, i Hassarmota, i Jarecha,
21 Hadoramu, Usali, Dikla,
I Adorama, i Uzala, i Dekla,
22 Ebali, Abimaeli, Ṣeba.
I Hebala, i Abimaela, i Sebaja,
23 Ofiri, Hafila, àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
I Ofira, i Hewila, i Jobaba. Ci wszyscy byli synowie Jektanowi.
24 Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,
Sem, Arfachsad, Selech.
25 Eberi, Pelegi. Reu,
Heber, Peleg, Rechu,
26 Serugu, Nahori, Tẹra,
Sarug, Nachor, Tare,
27 àti Abramu (tí ń ṣe Abrahamu).
Abram; ten jest Abraham.
28 Àwọn ọmọ Abrahamu: Isaaki àti Iṣmaeli.
Synowie Abrahamowi: Izaak i Ismael.
29 Èyí ni àwọn ọmọ náà: Nebaioti àkọ́bí Iṣmaeli: Kedari, Adbeeli, Mibsamu,
A teć są rodzaje ich: Pierworodny Ismaelowy Nebajot, i Kiedar, i Abdeel, i Mabsam.
30 Miṣima, Duma, Massa, Hadadi, Tema,
Masma, i Duma, Massa, Hadad, i Tema,
31 Jeturi, Nafiṣi, àti Kedema. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Iṣmaeli.
Jetur, Nafis i Kiedma. Cić są synowie Ismaelowi.
32 Àwọn ọmọ Ketura, obìnrin Abrahamu: Simrani, Jokṣani Medani, Midiani Iṣbaki àti Ṣua. Àwọn ọmọ Jokṣani: Ṣeba àti Dedani.
A synowie Cetury, założnicy Abrahamowej, których porodziła: Zamram i Joksan, i Madan, i Midyjan, i Jesbok, i Suach. A synowie Joksanowi; Saba i Dedan.
33 Àwọn ọmọ Midiani: Efani, Eferi, Hanoku, Abida àti Eldaa. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Ketura.
Synowie też Madyjanowi: Hefa, i Hefer, i Henoch, i Abida, i Eldaa. Cić wszyscy są synowie Cetury.
34 Abrahamu sì jẹ́ baba Isaaki. Àwọn ọmọ Isaaki: Esau àti Israẹli.
I spłodził Abraham Izaaka. A synowie Izaakowi byli: Ezaw i Izrael.
35 Àwọn ọmọ Esau: Elifasi, Reueli, Jeuṣi, Jalamu, àti Kora.
A synowie Ezawowi: Elifas, Rehuel, i Jehus, i Jelom, i Kore.
36 Àwọn ọmọ Elifasi: Temani, Omari, Sefi, Gatamu àti Kenasi; láti Timna: Amaleki.
Synowie Elifasowi: Teman i Omar, Sefo i Gaatan, Kienaz i syn Tamny, to jest, Amalek.
37 Àwọn ọmọ Reueli: Nahati, Sera, Ṣamma àti Missa.
Synowie Rehuelowi: Nahat, Zara, Samma, i Meza.
38 Àwọn ọmọ Seiri: Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana, Diṣoni, Eseri àti Diṣani.
A synowie Seirowi: Lotan, i Sobal, i Sebeon, i Hana, i Dysson, i Eser, i Dysan.
39 Àwọn ọmọ Lotani: Hori àti Homamu: Timna sì ni arábìnrin Lotani.
A synowie Lotanowi: Chory, i Heman; a siostra Lotanowa była Tamna.
40 Àwọn ọmọ Ṣobali: Afiani, Manahati, Ebali, Ṣefo àti Onamu. Àwọn ọmọ Sibeoni: Aiah àti Ana.
Synowie Sobalowi: Halman, i Manaat, i Hewal, Sefo, i Onam; a synowie Sebeonowi: Ajai Ana.
41 Àwọn ọmọ Ana: Diṣoni. Àwọn ọmọ Diṣoni: Hemdani, Eṣbani, Itrani, àti Kerani.
Synowie Ana: Dyson; a synowie Dysona: Hamdan, i Eseban, i Jetran, i Charan.
42 Àwọn ọmọ Eseri: Bilhani, Saafani àti Akani. Àwọn ọmọ Diṣani: Usi àti Arani.
Synowie Eserowi: Balaan, i Zawan, Akan. Synowie Dysanowi: Hus i Aran.
43 Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu, kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli: Bela ọmọ Beori, orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.
Cić są królowie, którzy królowali w ziemi Edomskiej, przedtem niż królował król nad synami Izraelskimi: Bela, syn Beorowy, a imię miasta jego Dynhaba.
44 Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
A gdy umarł Bela, królował miasto niego Jobab, syn Zerachowy z Bosry.
45 Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
A gdy umarł Jobab, królował miasto niego Chusam z ziemi Temańskiej.
46 Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.
A gdy umarł Chusam, królował miasto niego Hadad, syn Badadowy, który poraził Madyjańczyków na polu Moabskiem; a imię miasta jego Hawid.
47 Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
A gdy umarł Hadad, królował miasto niego Samla z Masreki.
48 Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
A gdy umarł Samla, królował miasto niego Saul z Rechobot nad rzeką
49 Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani, ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
A gdy umarł Saul, królował miasto niego Balanan, syn Achoborowy.
50 Nígbà tí Baali-Hanani kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.
A gdy umarł Balanan, królował miasto niego Hadar; a imię miasta jego Pehu, imię też żony jego Mehetabel, córka Matredy, córki Mezaabowej.
51 Hadadi sì kú pẹ̀lú. Àwọn baálẹ̀ Edomu ni: baálẹ̀ Timna, baálẹ̀ Alfa, baálẹ̀ Jeteti
A gdy umarł Hadar, byli książętami w Edon: książę Tamna, książę Halwa, książę Jetet,
52 baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni.
Książę Oolibama, książę Ela, książę Pinon,
53 Baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,
Książę Kienaz, książę Teman, książę Mabsar,
54 Magdieli àti Iramu. Àwọn wọ̀nyí ni baálẹ̀ Edomu.
Książę Magdyjel, książę Hyram. Toć byli książęta Edomscy.

< 1 Chronicles 1 >