< 1 Chronicles 1 >

1 Adamu, Seti, Enoṣi,
Adam, Seth, Enos,
2 Kenani, Mahalaleli, Jaredi,
Kênân, Mahalalêl, Yéred,
3 Enoku, Metusela, Lameki, Noa.
Hénoc, Mathusalem, Lamec,
4 Àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
Noé, Sem, Cham et Japhet.
5 Àwọn ọmọ Jafeti ni: Gomeri, Magogu, Madai; Jafani, Tubali, Meṣeki àti Tirasi.
Enfants de Japhet: Gomer, Magog, Madaï, Yavân, Toubal, Méchec et Tirâs.
6 Àwọn ọmọ Gomeri ni: Aṣkenasi, Rifati àti Togarma.
Enfants de Gomer: Achkenaz, Difath et Togarma.
7 Àwọn ọmọ Jafani ni: Eliṣa, Tarṣiṣi, Kittimu, àti Dodanimu.
Enfants de Yavân: Elicha, Tharsis, Kittim et Rodanim.
8 Àwọn ọmọ Hamu ni: Kuṣi, Ejibiti, Puti, àti Kenaani.
Enfants de Cham: Kouch, Misraïm, Pout et Canaan.
9 Àwọn ọmọ Kuṣi ni: Seba, Hafila, Sabta, Raama, àti Sabteka. Àwọn ọmọ Raama: Ṣeba àti Dedani.
Enfants de Kouch: Seba, Havila, Sabta, Râma et Sabteca; enfants de Râma: Cheba et Dedân.
10 Kuṣi sì bí Nimrodu ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
Kouch engendra aussi Nemrod, celui qui, le premier, fut puissant sur la terre.
11 Ejibiti sì bí Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Naftuhimu,
Misraïm fut la souche des Loudim, des Anamim, des Lehabim, des Naftouhim,
12 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
des Pathrousim, des Kaslouhim (d’où sortirent les Philistins) et des Kaftorim.
13 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀, àti Heti,
Canaan engendra Sidon, son premier-né, Heth,
14 àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
puis le Jébuséen, l’Amorréen, le Ghirgachéen,
15 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
le Hévéen, l’Arkéen, le Sinéen,
16 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
l’Arvadéen, le Cemaréen et le Hamathéen.
17 Àwọn ọmọ Ṣemu ni: Elamu, Aṣuri, Arfakṣadi, Ludi àti Aramu. Àwọn ọmọ Aramu: Usi, Huli, Geteri, àti Meṣeki.
Enfants de Sem: Elam, Assur, Arphaxad, Loud, Aram, Ouç, Houl, Ghéter et Méchec.
18 Arfakṣadi sì bí Ṣela, Ṣela sì bí Eberi.
Arphaxad engendra Chélah, et Chélah engendra Eber.
19 Eberi sì bí ọmọ méjì: ọ̀kan ń jẹ́ Pelegi, nítorí ní ìgbà ọjọ́ rẹ̀ ni ilẹ̀ ya; orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Joktani.
A Eber il naquit deux fils. Le nom de l’un était Péleg, parce que de son temps fut partagée la terre; et le nom de son frère: Yoktân.
20 Joktani sì bí Almodadi, Ṣelefi, Hasarmafeti, Jera.
Yoktân engendra Almodad, Chélef, Haçarmaveth, Yérah,
21 Hadoramu, Usali, Dikla,
Hadoram, Ouzal, Dikla,
22 Ebali, Abimaeli, Ṣeba.
Ebal, Abimaêl, Cheba,
23 Ofiri, Hafila, àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
Ophir, Havila et Yobab. Tous ceux-là furent enfants de Yoktân.
24 Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,
Sem, Arphaxad, Chélah,
25 Eberi, Pelegi. Reu,
Eber, Péleg, Reou,
26 Serugu, Nahori, Tẹra,
Seroug, Nacor, Tharé,
27 àti Abramu (tí ń ṣe Abrahamu).
Abram, qui est identique à Abraham.
28 Àwọn ọmọ Abrahamu: Isaaki àti Iṣmaeli.
Enfants d’Abraham: Isaac et Ismaël.
29 Èyí ni àwọn ọmọ náà: Nebaioti àkọ́bí Iṣmaeli: Kedari, Adbeeli, Mibsamu,
Voici leurs générations: le premier-né d’Ismaël, Nebaïoth, puis Kédar, Adbeêl, Mibsam,
30 Miṣima, Duma, Massa, Hadadi, Tema,
Michma, Douma, Massa, Hadad, Têma,
31 Jeturi, Nafiṣi, àti Kedema. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Iṣmaeli.
Yetour, Nafich et Kêdma. Tels sont les fils d’Ismaël.
32 Àwọn ọmọ Ketura, obìnrin Abrahamu: Simrani, Jokṣani Medani, Midiani Iṣbaki àti Ṣua. Àwọn ọmọ Jokṣani: Ṣeba àti Dedani.
Enfants de Ketoura, concubine d’Abraham: elle enfanta Zimrân, Yokchân, Medân, Madiân, Yichbak et Chouah. Enfants de Yokchân: Cheba et Dedân.
33 Àwọn ọmọ Midiani: Efani, Eferi, Hanoku, Abida àti Eldaa. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Ketura.
Enfants de Madiân: Efa, Efer, Hanoc, Abida et Eldaa. Tous ceux-là furent les enfants de Ketoura.
34 Abrahamu sì jẹ́ baba Isaaki. Àwọn ọmọ Isaaki: Esau àti Israẹli.
Abraham engendra Isaac. Enfants d’Isaac: Esaü et Israël.
35 Àwọn ọmọ Esau: Elifasi, Reueli, Jeuṣi, Jalamu, àti Kora.
Enfants d’Esaü: Elifaz, Reouêl, Yeouch, Yâlam et Korah.
36 Àwọn ọmọ Elifasi: Temani, Omari, Sefi, Gatamu àti Kenasi; láti Timna: Amaleki.
Enfants d’Elifaz: Têmân, Omar, Cefi, Gâtam, Kenaz, Timna et Amalec.
37 Àwọn ọmọ Reueli: Nahati, Sera, Ṣamma àti Missa.
Enfants de Reouêl: Nahath, Zérah, Chamma et Mizza.
38 Àwọn ọmọ Seiri: Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana, Diṣoni, Eseri àti Diṣani.
Enfants de Séir: Lotân, Chobal, Cibôn, Ana, Dichôn, Ecer et Dichân.
39 Àwọn ọmọ Lotani: Hori àti Homamu: Timna sì ni arábìnrin Lotani.
Enfants de Lotân: Hori et Homam; la sœur de Lotân était Timna.
40 Àwọn ọmọ Ṣobali: Afiani, Manahati, Ebali, Ṣefo àti Onamu. Àwọn ọmọ Sibeoni: Aiah àti Ana.
Enfants de Chobal: Alyân, Manahath, Ebal, Chefi et Onam. Enfants de Cibôn: Ayya et Ana.
41 Àwọn ọmọ Ana: Diṣoni. Àwọn ọmọ Diṣoni: Hemdani, Eṣbani, Itrani, àti Kerani.
Enfants de Ana: Dichôn… Enfants de Dichôn: Hamrân, Echbân, Yithrân et Kerân.
42 Àwọn ọmọ Eseri: Bilhani, Saafani àti Akani. Àwọn ọmọ Diṣani: Usi àti Arani.
Enfants d’Ecer: Bilhân, Zaavân et Yaakân. Enfants de Dichôn: Ouç et Arân.
43 Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu, kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli: Bela ọmọ Beori, orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.
Ce sont ici les rois qui régnèrent dans le pays d’Edom, avant qu’un roi régnât sur les enfants d’Israël: Béla, fils de Beor. Le nom de sa ville natale était Dinhaba.
44 Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Béla étant mort, à sa place régna Yobab, fils de Zérah, de Boçra.
45 Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Yobab étant mort, à sa place régna Houcham, du pays des Témanites.
46 Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.
Houcham étant mort, à sa place régna Hadad, fils de Bedad, qui défit Madiân dans la campagne de Moab. Le nom de sa ville était Avith.
47 Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Hadad étant mort, à sa place régna Samla, de Masrêka.
48 Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Samla étant mort, à sa place régna Chaoul, de Rehoboth-sur-le-Fleuve.
49 Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani, ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Chaoul étant mort, à sa place régna Baal-Hanân, fils d’Akhbor.
50 Nígbà tí Baali-Hanani kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.
Baal-Hanân étant mort à sa place régna Hadad, dont la ville avait nom Pâï et dont la femme s’appelait Mehêtabel, fille de Matred, fille de Mê-Zahab.
51 Hadadi sì kú pẹ̀lú. Àwọn baálẹ̀ Edomu ni: baálẹ̀ Timna, baálẹ̀ Alfa, baálẹ̀ Jeteti
Hadad mourut, et voici quels furent les chefs d’Edom: le chef Timna, le chef Alva, le chef Yethêth,
52 baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni.
le chef Oholibama, le chef Ela, le chef Pinôn,
53 Baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,
le chef Kenaz, le chef Têmân, le chef Mibçar,
54 Magdieli àti Iramu. Àwọn wọ̀nyí ni baálẹ̀ Edomu.
le chef Magdiêl, le chef Iram. Tels furent les chefs d’Edom.

< 1 Chronicles 1 >