< Zǝbur 39 >
1 Nǝƣmiqilǝrning bexi Yǝdutunƣa tapxurulƣan, Dawut yazƣan küy: — «Tilim gunaⱨ ⱪilmisun dǝp, Yollirimƣa diⱪⱪǝt ⱪilimǝn; Rǝzillǝr kɵz aldimda bolsa, mǝn aƣzimƣa bir kɵxǝk salimǝn» — degǝnidim.
Fún adarí orin. Fún Jedutuni. Saamu Dafidi. Mo wí pé, “Èmi yóò ṣọ́ ọ̀nà mi kí èmi kí ó má fi ahọ́n mi ṣẹ̀; èmi yóò fi ìjánu kó ara mi ní ẹnu níwọ̀n ìgbà tí ènìyàn búburú bá ń bẹ ní iwájú mi.”
2 Mǝn süküt ⱪilip, zuwan sürmidim, Ⱨǝtta yahxiliⱪ toƣrisidiki sɵzlǝrnimu aƣzimdin qiⱪarmidim; Biraⱪ dil azabim tehimu ⱪozƣaldi.
Mo fi ìdákẹ́ ya odi; mo tilẹ̀ pa ẹnu mi mọ́ kúrò nínú ọ̀rọ̀ rere; ìbànújẹ́ mi sì pọ̀ sí i.
3 Kɵnglümdǝ zǝrdǝm ⱪaynidi, Oylanƣanseri ot bolup yandi; Andin tilim ihtiyarsiz sɵzlǝp kǝtti.
Àyà mi gbóná ní inú mi. Nígbà tí mo ń ṣàṣàrò, iná ràn; nígbà náà ni mo fi ahọ́n mi sọ̀rọ̀:
4 I Pǝrwǝrdigar, ɵz ǝjilimni, Künlirimning ⱪanqilik ikǝnlikini manga ayan ⱪilƣin; Ajiz insan balisi ikǝnlikimni manga bildürgin.
“Olúwa, jẹ́ kí èmi kí ó mọ òpin mi, àti ìwọ̀n ọjọ́ mi, bí ó ti rí kí èmi kí o le mọ ìgbà tí mó ní níhìn-ín.
5 Mana, Sǝn künlirimni pǝⱪǝt nǝqqǝ ƣeriqla ⱪilding, Sening aldingda ɵmrüm yoⱪ ⱨesabididur. Bǝrⱨǝⱪ, barliⱪ insanlar tik tursimu, pǝⱪǝt bir tiniⱪla, halas. (Selaⱨ)
Ìwọ ti ṣe ayé mi bí ìbú àtẹ́lẹwọ́, ọjọ́ orí mi sì dàbí asán ní iwájú rẹ. Dájúdájú olúkúlùkù ènìyàn nínú ìjókòó rere rẹ̀ jásí asán pátápátá. (Sela)
6 Bǝrⱨǝⱪ, ⱨǝrbir insanning ⱨayati huddi bir kɵlǝnggidur, Ularning aldirap-saldiraxliri biⱨudǝ awariqiliktur; Ular bayliⱪlarni toplaydu, lekin keyin bu bayliⱪlarni kimning ⱪoliƣa juƣlinidiƣanliⱪini bilmǝydu.
“Nítòótọ́ ni olúkúlùkù ń rìn kiri bí òjìji. Nítòótọ́ ni wọ́n ń yọ ara wọn lẹ́nu lórí asán; wọ́n ń kó ọrọ̀ jọ, wọn kò sì mọ ẹni tí yóò ko lọ.
7 I Rǝb, ǝmdi mǝn nemini kütimǝn? Mening ümidim sangila baƣliⱪtur.
“Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí, Olúwa, kín ni mo ń dúró dè? Ìrètí mí ń bẹ ní ọ̀dọ̀ rẹ.
8 Meni barliⱪ asiyliⱪlirimdin ⱪutⱪuzƣaysǝn, Meni ⱨamaⱪǝtlǝrning mǝshirisigǝ ⱪaldurmiƣaysǝn.
Gbà mí lọ́wọ́ ìrékọjá mi gbogbo. Kí o má sì sọ mí di ẹni ẹ̀gàn àwọn ènìyàn búburú.
9 Süküt ⱪilip zuwan sürmidim; Qünki mana, muxu [jazani] Ɵzüng yürgüzgǝnsǝn.
Mo dákẹ́ jẹ́ẹ́; èmi kò sì ya ẹnu mi, nítorí wí pé ìwọ ni ó ṣe é.
10 Meni salƣan wabayingni mǝndin neri ⱪilƣaysǝn; Qünki ⱪolungning zǝrbisi bilǝn tügixǝy dǝp ⱪaldim.
Mú pàṣán rẹ kúrò ní ara mi; èmí ṣègbé tán nípa lílù ọwọ́ rẹ.
11 Sǝn tǝnbiⱨliring bilǝn kixini ɵz yamanliⱪi üqün tǝrbiyiliginingdǝ, Sǝn huddi nǝrsilǝrgǝ küyǝ ⱪurti qüxkǝndǝk, uning izzǝt-ƣururini yoⱪ ⱪiliwetisǝn; Bǝrⱨǝⱪ, ⱨǝrbir adǝm bir tiniⱪla, halas. (Selaⱨ)
Ìwọ fi ìbáwí kìlọ̀ fún ènìyàn nítorí ẹ̀ṣẹ̀, ìwọ a mú ẹwà rẹ parun bí kòkòrò aṣọ; nítòótọ́ asán ni ènìyàn gbogbo.
12 I Pǝrwǝrdigar, duayimni angliƣaysǝn, Pǝryadimƣa ⱪulaⱪ salƣaysǝn! Kɵz yaxlirimƣa süküt ⱪilmiƣaysǝn! Qünki mǝn pütkül ata-bowilirimdǝk, Sening aldingda yaⱪa yurtluⱪ, musapirmǝn, halas!
“Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa, kí o sì fetí sí igbe mi; kí o má ṣe di etí rẹ sí ẹkún mi. Nítorí àlejò ni èmi lọ́dọ̀ rẹ, àti àtìpó, bí gbogbo àwọn baba mi ti rí.
13 Manga tikkǝn kɵzüngni mǝndin neri ⱪilƣaysǝnki, Mǝn barsa kǝlmǝs jayƣa kǝtküqǝ, Meni bir’az bolsimu raⱨǝttin bǝⱨrimǝn ⱪilƣaysǝn.
Dá mi sí, kí èmi lè ní agbára, kí èmi tó lọ kúrò níhìn-ín yìí, àti kí èmi ó tó ṣe aláìsí.”