< Lawiylar 22 >
1 Pǝrwǝrdigar Musaƣa sɵz ⱪilip mundaⱪ dedi: —
Olúwa sọ fún Mose pé,
2 Sǝn Ⱨarun bilǝn uning oƣulliriƣa mundaⱪ degin: — «Silǝr Israillarning Manga atiƣan muⱪǝddǝs ⱨǝdiyǝlǝrni eⱨtiyatqanliⱪ bilǝn bir tǝrǝp ⱪilinglar, bolmisa ular namimni bulƣixi mumkin. Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn».
“Sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ kí wọ́n fi ọ̀wọ̀ fún ọrẹ mímọ́ tí àwọn ọmọ Israẹli yà sọ́tọ̀ fún mi, kí wọ́n má ba à ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́. Èmi ni Olúwa.
3 Ularƣa mundaⱪ degin: — «Silǝr ⱨǝrbir dǝwrlǝrdǝ, barliⱪ nǝsillinglardin ⱨǝrⱪaysisi Israillar Pǝrwǝrdigarƣa atiƣan pak nǝrsilǝrgǝ napak ⱨalǝttǝ yeⱪinlaxsa, undaⱪ kixi Mening aldimdin üzüp taxlinidu. Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn.
“Sọ fún wọn pé, ‘Fún àwọn ìran tí ń bọ̀. Bí ẹnikẹ́ni nínú àwọn ọmọ yín tí kò mọ́ bá wá sí ibi ọrẹ mímọ́ tí àwọn ara Israẹli ti yà sọ́tọ̀ fún Olúwa, kí ẹ yọ ẹni náà kúrò nínú iṣẹ́ àlùfáà ní iwájú mi. Èmi ni Olúwa.
4 Ⱨarunning nǝslidin biri pesǝ-mahaw yaki aⱪma kesili bolƣan bolsa, pak bolmiƣuqǝ muⱪǝddǝs nǝrsilǝrdin yemisun. Birkim ɵlükning sǝwǝbidin napak bolƣan birkimgǝ wǝ yaki mǝniysi eⱪip kǝtkǝn kixigǝ tegip kǝtsǝ,
“‘Bí ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Aaroni bá ní ààrùn ara tí ń ran ni, tàbí ìtújáde nínú ara. Ó lè má jẹ ọrẹ mímọ́ náà títí di ìgbà tí a ó fi wẹ̀ ẹ́ mọ́. Òun tún lè di aláìmọ́ bí ó bá fọwọ́ kan ohunkóhun tí òkú nǹkan bá sọ di àìmọ́ tàbí bí ó bá farakan ẹnikẹ́ni tí ó ní ìtújáde.
5 yaki adǝmni napak ⱪilidiƣan ɵmiligüqi janiwarƣa tǝgsǝ yaki ⱨǝrⱪandaⱪ yuⱪup ⱪalidiƣan napakliⱪi bar bir adǝmgǝ tegip kǝtsǝ, (napakliⱪi nemidin boluxidin ⱪǝt’iynǝzǝr)
Tàbí bí ó bá fọwọ́ kan èyíkéyìí nínú ohun tí ń rákò, tí ó sọ ọ́ di aláìmọ́, tàbí ẹnikẹ́ni tí ó sọ ọ́ di àìmọ́, ohunkóhun yówù kí àìmọ́ náà jẹ́.
6 mundaⱪ nǝrsilǝrgǝ tǝgkǝn kixi kǝq kirgüqǝ napak bolup, muⱪǝddǝs nǝrsilǝrdin yemisun. U bǝdinini suda yusun
Ẹni náà tí ó fọwọ́ kan irú nǹkan bẹ́ẹ̀ yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. Kò gbọdọ̀ jẹ èyíkéyìí nínú ọrẹ mímọ́ àyàfi bí ó bá wẹ ara rẹ̀.
7 andin kün olturƣanda pak sanilip, muⱪǝddǝs nǝrsilǝrdin yeyixkǝ bolidu; qünki bular uning ozuⱪidur.
Bí oòrùn bá wọ̀, ẹni náà di mímọ́, lẹ́yìn náà ni ó tó le jẹ ọrẹ mímọ́, torí pé wọ́n jẹ́ oúnjẹ rẹ̀.
8 U [ɵzlükidin] ɵlgǝn wǝ yaki yirtⱪuqlar boƣup ⱪoyƣan ⱨaywanni yeyix bilǝn ɵzini napak ⱪilmisun. Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn.
Kò gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun tí ó bá ti kú sílẹ̀, tàbí tí ẹranko fàya, kí ó sì tipa bẹ́ẹ̀ di aláìmọ́. Èmi ni Olúwa.
9 Ular Mening bu tapiliƣanlirimni tutuxi kerǝk; bolmisa, buningƣa ihlassizliⱪ ⱪilsa, [xu ɵlük] tüpǝylidin gunaⱨkar bolup ɵlidu; ularni muⱪǝddǝs ⱪilƣuqi Pǝrwǝrdigar Ɵzümdurmǝn.
“‘Kí àwọn àlùfáà pa ìlànà mi mọ́, kí wọn má ba à jẹ̀bi, kí wọn sì kú nítorí pé wọ́n ṣe ọrẹ wọ̀nyí pẹ̀lú fífojútẹ́ńbẹ́lú wọn. Èmi ni Olúwa tí ó sọ wọ́n di mímọ́.
10 Kaⱨinlarƣa yat bolƣan ⱨeqⱪandaⱪ kixi muⱪǝddǝs nǝrsilǝrdin yemisun. Kaⱨinning yenidiki musapir-meⱨman wǝ yaki mǝdikari bolsun ularmu muⱪǝddǝs nǝrsilǝrdin yemisun.
“‘Kò sí ẹnikẹ́ni lẹ́yìn ìdílé àlùfáà tí ó le jẹ ọrẹ mímọ́ náà, bẹ́ẹ̀ ni, àlejò àlùfáà tàbí alágbàṣe rẹ̀ kò le jẹ ẹ́.
11 Ⱨalbuki, kaⱨin ɵzi pul qiⱪirip setiwalƣan ⱪul uningdin yeyixkǝ bolidu; xuningdǝk uning ɵyidǝ tuƣulƣan kiximu uningdin yesǝ bolidu.
Ṣùgbọ́n bí àlùfáà bá ra ẹrú, pẹ̀lú owó, tàbí tí a bí ẹrú kan nínú ìdílé rẹ̀, ẹrú náà lè jẹ oúnjẹ rẹ̀.
12 Kaⱨinning ⱪizi yat kixigǝ tǝgkǝn bolsa umu «kɵtürmǝ ⱨǝdiyǝ» süpitidǝ atalƣan muⱪǝddǝs nǝrsilǝrdin yemisun.
Bí ọmọbìnrin àlùfáà bá fẹ́ ẹni tí kì í ṣe àlùfáà, kò gbọdọ̀ jẹ nínú èyíkéyìí nínú ohun ọrẹ mímọ́.
13 Lekin ǝgǝr kaⱨinning ⱪizi tul bolup ⱪelip, yaki ⱪoyup berilip pǝrzǝntsiz ⱨalǝttǝ atisining ɵyigǝ yenip kelip, yax waⱪtidikidǝk olturƣan bolsa, undaⱪta atisining taamidin yeyǝlǝydu; lekin ⱨeqbir yat kixi uningdin yemǝsliki kerǝk.
Ṣùgbọ́n bí ọmọbìnrin àlùfáà bá jẹ́ opó tàbí tí a ti kọ ọ́ sílẹ̀, ṣùgbọ́n tí kò lọ́mọ tí ó sì padà sínú ilé baba rẹ̀ láti máa gbé bẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìgbà èwe rẹ̀, ó le jẹ oúnjẹ baba rẹ̀. Bí ó ti wù kí ó rí, àlejò tí kò lẹ́tọ̀ọ́ kò gbọdọ̀ jẹ èyíkéyìí nínú oúnjẹ náà.
14 Əgǝr birkim bilmǝy, muⱪǝddǝs nǝrsilǝrdin yǝp salsa, undaⱪta u uningƣa xuning bǝxtin birini ⱪoxup, muⱪǝddǝs nǝrsining ɵzi bilǝn kaⱨinƣa ⱪayturup bǝrsun.
“‘Bí ẹnikẹ́ni bá ṣèèṣì jẹ ọrẹ mímọ́ kan, ó gbọdọ̀ ṣe àtúnṣe lórí ẹbọ náà fún àlùfáà, kí ó sì fi ìdámárùn-ún ohun tí ọrẹ náà jẹ́ kún un.
15 [Kaⱨinlar] Israillarning Pǝrwǝrdigarƣa atiƣan nǝrsilirini bulƣimasliⱪi kerǝk;
Àwọn àlùfáà kò gbọdọ̀ sọ ọrẹ mímọ́ tí àwọn ọmọ Israẹli mú wá síwájú Olúwa di àìmọ́.
16 bolmisa, hǝlⱪ muⱪǝddǝs ⱨǝdiyilǝrdin yeyixi bilǝn, kaⱨinlar hǝlⱪning gǝdinigǝ itaǝtsizlik gunaⱨini yüklǝp ⱪoyƣan bolidu; qünki ularni muⱪǝddǝs ⱪilƣuqi Pǝrwǝrdigar Ɵzümdurmǝn».
Nípa fífi ààyè fún wọn láti jẹ ọrẹ mímọ́ náà, kí wọ́n sì tipa bẹ́ẹ̀ mú ẹ̀bi tí wọn yóò san nǹkan fún wá sórí wọn. Èmi ni Olúwa, tí ó sọ wọ́n di mímọ́.’”
17 Pǝrwǝrdigar Musaƣa sɵz ⱪilip mundaⱪ dedi: —
Olúwa sọ fún Mose pé,
18 Sǝn Ⱨarun bilǝn uning oƣulliri wǝ Israillarning ⱨǝmmisigǝ mundaⱪ degin: — Əgǝr Israil jǝmǝtidin biri wǝ yaki Israil zeminida turuwatⱪan musapirlarning biri ɵz ⱪǝsǝmlirigǝ baƣliⱪ ⱪurbanliⱪ yaki ihtiyariy ⱪurbanliⱪni sunup, Pǝrwǝrdigarƣa atap kɵydürmǝ ⱪurbanliⱪ ⱪilmaⱪqi bolsa,
“Sọ fún Aaroni, àwọn ọmọ rẹ̀ àti fún gbogbo Israẹli kí o sì wí fún wọn pé, ‘Bí ẹnikẹ́ni nínú yín yálà ọmọ Israẹli ni tàbí àlejò tí ń gbé ní Israẹli bá mú ẹ̀bùn wá fún ọrẹ ẹbọ sísun sí Olúwa, yálà láti san ẹ̀jẹ́ tàbí ọrẹ àtinúwá.
19 undaⱪta u ⱪobul ⱪilinixi üqün bejirim ǝrkǝk kala, ⱪoy yaki ɵqkilǝrdin kǝltürünglar.
Ẹ gbọdọ̀ mú akọ láìní àbùkù láti ara màlúù, àgùntàn tàbí ewúrẹ́, kí ó ba à lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún yín.
20 Əyibi bolmiƣan bir janiwarni sunuxunglar kerǝk; qünki xundaⱪ bolƣini silǝr üqün ⱪobul ⱪilinmas.
Ẹ má ṣe mú ohunkóhun tí ó ní àbùkù wá, torí pé kò ní jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún yín.
21 Birsi kalilardin yaki uxxaⱪ maldin ɵz ⱪǝsǝmlirigǝ baƣliⱪ ⱪurbanliⱪ yaki ihtiyariy ⱪurbanliⱪni sunup, Pǝrwǝrdigarƣa atap inaⱪliⱪ ⱪurbanliⱪi ⱪilmaⱪqi bolsa, sunulƣan ⱨaywan ⱪobul ⱪilinixi üqün bejirim boluxi kerǝk; uning ⱨeqⱪandaⱪ ǝyibi bolmisun.
Bí ẹnikẹ́ni bá mú ọrẹ àlàáfíà wá láti inú agbo màlúù tàbí ti àgùntàn, fún Olúwa láti san ẹ̀jẹ́ pàtàkì tàbí fún ọrẹ àtinúwá. Ó gbọdọ̀ jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà láìní àbùkù.
22 Kor yaki aⱪsaⱪ-qolaⱪ, qonaⱪ yaki yarisi yiringdap kǝtkǝn, tǝmrǝtkǝ basⱪan yaki ⱪotur-qaⱪa besip ⱪalƣan ⱨaywanlar bolsa — bularni Pǝrwǝrdigarƣa atap sunsanglar yaki bularni Pǝrwǝrdigarƣa atap ⱪurbanliⱪ süpitidǝ ⱪurbangaⱨta otta kɵydürsǝnglar bolmaydu.
Ẹ má ṣe fi ẹranko tí ó fọ́jú, tí ó fi ara pa, tí ó yarọ, tí ó ní kókó, tí ó ní èkúkú, èépá àti egbò kíkẹ̀ rú ẹbọ sí Olúwa. Ẹ kò gbọdọ̀ gbé èyíkéyìí nínú wọn sórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ bi ọrẹ tí a fi iná ṣe sí Olúwa.
23 Torpaⱪ yaki ⱪoyning mǝlum jüp ǝzasidin biri uzunraⱪ ya ⱪisⱪa bolsa, mundaⱪlarni ihtiyariy ⱪurbanliⱪ süpitidǝ ɵtküzsǝng bolidu, lekin ⱪǝsǝmgǝ baƣliⱪ bolsa ⱪurbanliⱪ üqün ⱪobul ⱪilinmas.
Ẹ le mú màlúù tàbí àgùntàn tí ó ní àbùkù tàbí tí ó yọ iké wá fún ọrẹ àtinúwá, ṣùgbọ́n kò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún ọrẹ ẹ̀jẹ́.
24 Uruⱪdini zǝhimlǝngǝn, ezilip kǝtkǝn, yerilƣan yaki piqilƣan ⱨaywanni Pǝrwǝrdigarƣa atap ⱪurbanliⱪ ⱪilmanglar. Mundaⱪ ixni ɵz zemininglardimu ⱨǝrgiz ⱪilmanglar.
Ẹ má ṣe fi ẹranko tí kóró ẹpọ̀n rẹ̀ fọ́ tàbí tí a tẹ̀, tàbí tí a yà tàbí tí a là rú ẹbọ sí Olúwa. Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe èyí ní ilẹ̀ yín.
25 Hudayinglarning neni süpitidǝ yaⱪa yurtluⱪ kixining ⱪolidin xundaⱪ ⱨaywanlardin ⱨeqⱪaysisini elip sunmanglar; qünki ular meyip bolƣaqⱪa, silǝr üqün ⱪobul ⱪilinmaydu.
Ẹ kò gbọdọ̀ gba irú ẹranko bẹ́ẹ̀ lọ́wọ́ àlejò kankan láti fi rú ẹbọ gẹ́gẹ́ bí oúnjẹ sí Ọlọ́run yín. A kò nígbà wọ́n fún yín nítorí pé wọ́n ní àbùkù, wọ́n sì díbàjẹ́.’”
26 Pǝrwǝrdigar Musaƣa sɵz ⱪilip mundaⱪ dedi: —
Olúwa sọ fún Mose pé,
27 Bir mozay, ⱪoza yaki oƣlaⱪ tuƣulsa yǝttǝ küngiqǝ anisini ǝmsun; sǝkkizinqi künidin baxlap Pǝrwǝrdigarƣa atap otta sunidiƣan ⱪurbanliⱪ süpitidǝ ⱪobul boluxⱪa yaraydu.
“Nígbà tí màlúù bá bímọ, tí àgùntàn bímọ, tí ewúrẹ́ sì bímọ, ọmọ náà gbọdọ̀ wà pẹ̀lú ìyá rẹ̀ fún ọjọ́ méje. Láti ọjọ́ kẹjọ ni ó ti di ìtẹ́wọ́gbà fún ọrẹ àfinásun sí Olúwa.
28 Mǝyli kala bolsun, ⱪoy bolsun, silǝr anisi bilǝn balisini bir kündǝ boƣuzlimanglar.
Ẹ má ṣe pa màlúù àti ọmọ rẹ̀ tàbí àgùntàn àti ọmọ rẹ̀ ní ọjọ́ kan náà.
29 Silǝr Pǝrwǝrdigarƣa atap bir tǝxǝkkür ⱪurbanliⱪi sunmaⱪqi bolsanglar, ⱪobul ⱪilinixⱪa layiⱪ bolƣan yol bilǝn sununglar.
“Nígbà tí ẹ bá rú ẹbọ ọpẹ́ sí Olúwa, ẹ rú u ní ọ̀nà tí yóò fi jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún yín.
30 U sunulƣan künidǝ yeyilixi kerǝk; uningdin ⱨeqnemini ǝtisigǝ ⱪaldurmasliⱪinglar kerǝk. Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn.
Ẹ gbọdọ̀ jẹ ẹ́ ní ọjọ́ náà gan an, ẹ má ṣe ṣẹ́ ọ̀kankan kù di àárọ̀. Èmi ni Olúwa.
31 Silǝr Mening ǝmrlirimni qing tutup, ularƣa ǝmǝl ⱪilinglar. Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn.
“Ẹ pa òfin mi mọ́, kí ẹ sì máa ṣe wọ́n. Èmi ni Olúwa.
32 Mening muⱪǝddǝs namimni bulƣimanglar, Mǝn ǝmdi Israillarning arisida muⱪǝddǝs dǝp bilinimǝn. Mǝn silǝrni muⱪǝddǝs ⱪilƣuqi Pǝrwǝrdigar bolup,
Ẹ má ṣe ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́. Àwọn ọmọ Israẹli gbọdọ̀ mọ̀ mí ní mímọ́. Èmi ni Olúwa tí ó sọ yín di mímọ́.
33 Hudayinglar boluxⱪa silǝrni Misir zeminidin qiⱪirip kǝldim. Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn.
Tí ó sì mú yín jáde láti Ejibiti wá láti jẹ́ Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa.”