< Yǝrǝmiya 34 >
1 Babil padixaⱨi Neboⱪadnǝsar, pütün ⱪoxuni wǝ ⱨɵkümranliⱪiƣa beⱪinƣan barliⱪ padixaⱨliⱪlar wǝ ǝllǝrning ⱨǝmmisi Yerusalemƣa wǝ uning ǝtrapidiki barliⱪ xǝⱨǝrlǝrgǝ jǝng ⱪilƣan waⱪtida, Pǝrwǝrdigardin Yǝrǝmiyaƣa kǝlgǝn sɵz: —
Nígbà tí Nebukadnessari ọba Babeli àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, pẹ̀lú gbogbo ìjọba àti àwọn ènìyàn ní ilẹ̀ ọba tí ó jẹ ọba lé lórí ń bá Jerusalẹmu jà, àti gbogbo àwọn ìlú tí ó yíká, ọ̀rọ̀ yìí tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa pé:
2 Israilning Hudasi Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Zǝdǝkiyaning yeniƣa berip uningƣa mundaⱪ degin: — Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Mana, bu xǝⱨǝrni Babil padixaⱨining ⱪoliƣa tapxurimǝn, u uningƣa ot ⱪoyup kɵydüriwetidu.
“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli ọmọ-ogun wí: Lọ sí ọ̀dọ̀ Sedekiah ọba Juda kí o sì sọ fún un pé, ‘Èyí ni ohun tí Ọlọ́run wí: Èmi fẹ́ fa ìlú yìí lé ọba Babeli lọ́wọ́, yóò sì jó palẹ̀.
3 Sǝn bolsang, uning ⱪolidin ⱪaqalmaysǝn; bǝlki sǝn tutulup uning ⱪoliƣa tapxurulisǝn; sening kɵzliring Babil padixaⱨining kɵzlirigǝ ⱪaraydu, uning bilǝn yüz turanǝ sɵzlixisǝn wǝ sǝn Babilƣa sürgün bolup ketisǝn.
Ìwọ kò ní sá àsálà, ṣùgbọ́n à ó mú ọ, bẹ́ẹ̀ ni a ó sì fà ọ́ lé e lọ́wọ́. Ìwọ yóò rí ọba Babeli pẹ̀lú ojú ara rẹ; yóò sì bá ọ sọ̀rọ̀ lójúkojú; ìwọ yóò sì lọ sí Babeli.
4 Lekin, i Yǝⱨuda padixaⱨi Zǝdǝkiya, Pǝrwǝrdigarning sɵzini angla; Pǝrwǝrdigar sening tuƣrangda mundaⱪ dǝydu: — Sǝn ⱪiliq bilǝn ɵlmǝysǝn;
“‘Síbẹ̀, gbọ́ ìlérí Olúwa, ìwọ Sedekiah ọba Juda. Èyí ni ohun tí Ọlọ́run wí nípa rẹ; ìwọ kì yóò ti ipa idà kú;
5 sǝn aman-tinqliⱪta ɵlisǝn; ata-bowiliring bolƣan ɵzüngdin ilgiriki padixaⱨlar üqün matǝm tutup huxbuy yaⱪⱪandǝk ular ohxaxla sǝn üqünmu [huxbuy] yaⱪidu; ular sǝn üqün: «Aⱨ, xaⱨim!» dǝp matǝm tutidu; qünki Mǝn xundaⱪ wǝdǝ ⱪilƣanmǝn, — dǝydu Pǝrwǝrdigar.
ìwọ yóò kú ní àlàáfíà. Bí àwọn ènìyàn sì ti ń ṣe iná ìsìnkú ní ọlá fún àwọn baba rẹ, ọba tí ó jẹ ṣáájú rẹ, bẹ́ẹ̀ ni wọn yóò ṣe iná ní ọlá rẹ, wọn ó sì pohùnréré pé, “Yé, olúwa!” Èmi fúnra mi ni ó ṣèlérí yìí ni Olúwa wí.’”
6 Andin Yǝrǝmiya pǝyƣǝmbǝr bu sɵzlǝrning ⱨǝmmisini Yǝⱨuda padixaⱨi Zǝdǝkiyaƣa Yerusalemda eytti.
Nígbà náà ni Jeremiah wòlíì sọ gbogbo nǹkan yìí fún Sedekiah ọba Juda ní Jerusalẹmu.
7 Xu qaƣda Babil padixaⱨining ⱪoxuni Yerusalemda wǝ Yǝⱨudadiki ⱪalƣan xǝⱨǝrlǝrdǝ, yǝni Laⱪixta wǝ Azikaⱨta jǝng ⱪiliwatatti; qünki Yǝⱨudadiki mustǝⱨkǝm xǝⱨǝrlǝr arisidin pǝⱪǝt bularla ixƣal bolmiƣanidi.
Nígbà tí ogun ọba Babeli ń bá Jerusalẹmu jà, àti gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó kù ní Juda, Lakiṣi, Aseka; àwọn nìkan ni ìlú olódi tí ó kù ní Juda.
8 Padixaⱨ Zǝdǝkiya [ⱪullirimizƣa] azadliⱪ jakarlayli dǝp Yerusalemdikilǝrning ⱨǝmmisi bilǝn ǝⱨdini kesip tüzgǝndin keyin, Pǝrwǝrdigardin tɵwǝndiki bu sɵz Yǝrǝmiyaƣa kǝldi
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá lẹ́yìn ìgbà tí ọba Sedekiah ti dá májẹ̀mú pẹ̀lú gbogbo àwọn ènìyàn ní Jerusalẹmu láti polongo ìtúsílẹ̀ fún àwọn ẹrú.
9 (ǝⱨdǝ boyiqǝ ⱨǝrbiri ɵz ibraniy ⱪullirini, ǝr bolsun, ⱪiz-ayal bolsun, ⱪoyuwetixi kerǝk idi; ⱨeqⱪaysisi ɵz ⱪerindixi bolƣan Yǝⱨudiyni ⱪulluⱪta ⱪaldurmasliⱪi kerǝk idi.
Kí oníkálùkù lè jẹ́ kí ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin tí í ṣe Heberu lọ lọ́fẹ̀ẹ́, kí ẹnikẹ́ni kí ó má mú ará Juda arákùnrin rẹ̀ sìn.
10 Əⱨdigǝ ⱪoxulƣan barliⱪ ǝmirlǝr wǝ barliⱪ hǝlⱪ xuningƣa, yǝni ⱨǝrⱪaysimiz ɵz ⱪuli yaki dedikini ⱪoyuwetǝyli, ularni ⱪulluⱪta ⱪalduruwǝrmǝyli degǝn sɵzigǝ boysundi. Ular boysunup ularni ⱪoyuwǝtti.
Nítorí náà, gbogbo àwọn aláṣẹ àti àwọn ènìyàn tí wọ́n fi ọwọ́ sí májẹ̀mú náà láti dá ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin sílẹ̀ kí wọ́n sì má ṣe fi wọ́n sínú ìgbèkùn mọ́. Wọ́n sì gbà, wọ́n sì jẹ́ kí wọn lọ lọ́fẹ̀ẹ́.
11 Lekin uningdin keyin ular bu yoldin yenip ⱪoyuwǝtkǝn ⱪul-dedǝklǝrni ɵzigǝ ⱪayturuwaldi. Ular bularni ⱪaytidin mǝjburiy ⱪul-dedǝk ⱪiliwaldi).
Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, wọ́n yí ọkàn wọn padà; wọ́n sì mú àwọn ẹrú tí wọ́n ti dá sílẹ̀ padà láti tún máa sìn wọ́n.
12 — Xu qaƣda Pǝrwǝrdigarning sɵzi Yǝrǝmiyaƣa kelip mundaⱪ deyildi: —
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá wí pé:
13 Israilning Hudasi Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Mǝn ata-bowiliringlarni Misirning zeminidin, yǝni «ⱪulluⱪ ɵyi»din qiⱪarƣinimda, ular bilǝn ǝⱨdǝ tüzgǝnidim;
“Èyí ni ohun tí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli wí pé: Mo dá májẹ̀mú kan pẹ̀lú àwọn baba ńlá yín nígbà tí mo mú wọn kúrò ní Ejibiti; kúrò ní oko ẹrú. Mo wí pé,
14 [xu ǝⱨdǝ boyiqǝ] ⱨǝrbiringlar yǝttinqi yilida silǝrgǝ ɵzini satⱪan ⱨǝrⱪaysi ⱪerindixinglar bolƣan ibraniy kixilirini ⱪoyuwetixinglar kerǝk; u ⱪulluⱪungda altǝ yil bolƣandin keyin, sǝn uni azadliⱪⱪa ⱪoyuwetixing kerǝk, degǝnidim. Lekin ata-bowiliringlar buni anglimay ⱨeq ⱪulaⱪ salmiƣan.
‘Ní ọdún keje, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín gbọdọ̀ tú àwọn Heberu tí wọ́n ti ta ara wọn fún un yín sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti sìn yín fún ọdún mẹ́fà. Ẹ gbọdọ̀ jẹ́ kí wọn kí ó lọ’; ṣùgbọ́n àwọn baba yín kò gbọ́; bẹ́ẹ̀ ni wọn kò fetí sí mi.
15 Lekin silǝr bolsanglar, [xu yaman yoldin] yenip, kɵz aldimda durus ixni kɵrüp, ⱨǝrbiringlar ɵz yeⱪiniƣa «azad bol» dǝp jakarlidinglar, xuningdǝk Ɵz namim bilǝn atalƣan ɵydǝ ǝⱨdǝ tüzüdinglar;
Láìpẹ́ yìí ẹ ti ronúpìwàdà, ẹ sì ṣe ohun tí ó tọ́ lójú mi, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín sì ṣe ìtúsílẹ̀ fún àwọn ènìyàn. Ẹ sì tún bá mi dá májẹ̀mú ní àwọn ilé tí a ti ń pe orúkọ mi.
16 lekin silǝr yǝnǝ yenip Mening namimƣa daƣ kǝltürüp, ⱨǝrbiringlar ɵz rayiƣa ⱪoyuwǝtkǝn ⱪulni ⱨǝm ihtiyariƣa ⱪoyuwǝtkǝn dedǝkni ⱪayturuwelip ⱪaytidin ɵzünglarƣa ⱪul-dedǝk boluxⱪa mǝjburlidinglar.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin yípadà, ẹ sì sọ orúkọ mi di èérí, olúkúlùkù sì mú kí àwọn ẹni rẹ tí ó ti sọ di òmìnira bí ọkàn wọn ti fẹ́ padà; ẹ̀yin sì tún fi wọ́n ṣe ẹrú.
17 Xunga Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Silǝr manga ⱪulaⱪ salmidinglar, ⱨǝrbiringlar ɵz ⱪerindixinglarƣa, ⱨǝrbiringlar ɵz yeⱪininglarƣa azad bolunglar dǝp ⱨeq jakarlimidinglar; mana, Mǝn silǝrgǝ bir hil azadliⱪni — yǝni ⱪiliqⱪa, wabaƣa wǝ ⱪǝⱨǝtqilikkǝ bolƣan bir azadliⱪni jakarlaymǝn; silǝrni yǝr yüzidiki barliⱪ padixaⱨliⱪlarƣa bir wǝⱨxǝt basⱪuqi ⱪilimǝn.
“Nítorí náà báyìí ni Olúwa wí: Ẹ̀yin kò fetí sí mi nípa ọ̀rọ̀ òmìnira láàrín ẹ̀gbọ́n sí àbúrò, láàrín ẹnìkan sí èkejì rẹ̀. Wò ó, èmi yóò kéde òmìnira fún un yín ni Olúwa wí. Sí idà, sí àjàkálẹ̀-ààrùn, àti sí ìyàn, èmi ó sì fi yín fún ìwọ̀sí ní gbogbo ìjọba ilẹ̀ ayé.
18 Xuning bilǝn Mǝn ǝⱨdǝmni buzƣan, kɵz aldimda kesip tüzgǝn ǝⱨdining sɵzlirigǝ ǝmǝl ⱪilmiƣan kixilǝrni bolsa, ular ɵzliri soyup ikki parqǝ ⱪilip, otturisidin ɵtkǝn ⱨeliⱪi mozaydǝk ⱪilimǝn;
Èmi ó ṣe àwọn ọkùnrin náà tí ó da májẹ̀mú mi, tí kò tẹ̀lé májẹ̀mú tí wọ́n ti dá níwájú mi bí ẹgbọrọ màlúù tí wọ́n gé sí méjì, tí ó sì kọjá láàrín ìpín méjì náà.
19 Yǝⱨudaning ǝmirliri wǝ Yerusalemning ǝmirliri, ordidiki ǝlǝmdarlar, kaⱨinlar, xuningdǝk mozayning ikki parqisining otturisidin ɵtkǝn barliⱪ hǝlⱪni bolsa,
Àwọn ìjòyè Juda àti àwọn ti Jerusalẹmu, àwọn aláṣẹ àti àwọn àlùfáà àti gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà tí ó kọjá láàrín àwọn ìpín méjèèjì ẹgbọrọ màlúù náà.
20 Mǝn ularni düxmǝnlirining ⱪoliƣa, jenini izdigüqilǝrning ⱪoliƣa tapxurimǝn; xuning bilǝn jǝsǝtliri asmandiki uqar-ⱪanatlarƣa wǝ zemindiki ⱨaywanlarƣa ozuⱪ bolidu;
Èmi ó fi wọ́n lé ọwọ́ àwọn ọ̀tá wọn, àti lé àwọn tí ń wá ẹ̀mí wọn lọ́wọ́. Òkú wọn yóò jẹ́ oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run àti fún àwọn ẹranko igbó.
21 Yǝⱨuda padixaⱨi Zǝdǝkiya wǝ uning ǝmirlirinimu düxmǝnlirining ⱪoliƣa, jenini izdigüqilǝrning ⱪoliƣa, xundaⱪla silǝrgǝ ⱨujum ⱪilixtin qikinip turƣan Babil padixaⱨining ⱪoxunining ⱪoliƣa tapxurimǝn.
“Sedekiah ọba àti àwọn ìjòyè rẹ̀ ní Juda ni èmí yóò fi lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́, àti àwọn tí ń wá ẹ̀mí wọn àti lé ọwọ́ ogun Babeli tí ó ti lọ kúrò lọ́dọ̀ yín.
22 Mana, Mǝn ǝmr ⱪilimǝn, — dǝydu Pǝrwǝrdigar, wǝ ular bu xǝⱨǝr aldiƣa yǝnǝ kelidu; ular uningƣa ⱨujum ⱪilip ot ⱪoyup kɵydüriwetidu; wǝ Mǝn Yǝⱨudaning xǝⱨǝrlirini wǝyranǝ, ⱨeq adǝmzatsiz ⱪilimǝn.
Wò ó èmi ó pàṣẹ ni Olúwa wí, èmi ó sì mú wọn padà sí ìlú yìí, wọn ó sì bá a jà, wọn ó sì kó o, wọn ó fi iná jó o. Èmi ó sì sọ ìlú Juda dí ahoro.”