< Əzakiyal 25 >

1 Pǝrwǝrdigarning sɵzi manga kelip mundaⱪ deyildi: —
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
2 I insan oƣli, yüzüngni Ammoniylarƣa ⱪaritip, ularni ǝyiblǝp bexarǝt berip mundaⱪ degin: —
“Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí àwọn ará Ammoni kí ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí wọn.
3 — Ammoniylarƣa mundaⱪ degin — Rǝb Pǝrwǝrdigarning sɵzini anglanglar! Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Mening muⱪǝddǝs jayim bulƣanƣanda, Israil zemini wǝyran ⱪilinƣanda, Yǝⱨuda jǝmǝti sürgün ⱪilinƣanda sǝn ularƣa ⱪarap: «Waⱨ! Yahxi boldi!» degining tüpǝylidin,
Sì wí fún àwọn ará Ammoni pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè tí ó wí pé. Nítorí tí ìwọ wí pé, “Á hà!” Sí ibi mímọ́ mi nígbà tí ó di àìlọ́wọ̀ àti sí orí ilẹ̀ Israẹli nígbà tí ó di ahoro; àti sí ilẹ̀ Juda, nígbà tí wọ́n lọ sí ìgbèkùn,
4 ǝmdi mana, Mǝn seni xǝrⱪtiki ǝllǝrning igidarqiliⱪiƣa tapxurimǝn; ular sening arangda bargaⱨ ⱪurup, arangda qedirlirini tikidu; ular mewiliringni yǝp, sütüngni iqidu.
kíyèsi i, nítorí náà ni èmi yóò fi fi ọ lé àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn lọ́wọ́ ni ohun ìní. Wọn yóò sì gbé ààfin wọn kalẹ̀ nínú rẹ, wọn yóò sì gbé ibùgbé wọn nínú rẹ, wọn yóò jẹ èso rẹ, wọn yóò sì mu wàrà rẹ.
5 Mǝn Rabbaⱨ xǝⱨirini tɵgilǝr üqün otlaⱪ, Ammoniylarning yerini ⱪoy padiliri üqün aramgaⱨ ⱪilimǝn; xuning bilǝn silǝr Mening Pǝrwǝrdigar ikǝnlikimni tonup yetisilǝr.
Èmi yóò sì sọ Rabba di ibùjẹ, fún àwọn ìbákasẹ àti àwọn ọmọ Ammoni di ibùsùn fún agbo ẹran. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
6 — Qünki Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Qünki sǝn Israil zeminiƣa ⱪarap qawak qelip, putungni tepqǝklitip, ⱪǝlbingdiki pütün ɵqmǝnlik bilǝn hux bolƣanliⱪing tüpǝylidin,
Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí. Nítorí pé ìwọ pàtẹ́wọ́, ìwọ sì jan ẹsẹ̀ mọ́lẹ̀, tí ìwọ ń yọ̀ pẹ̀lú gbogbo àrankàn rẹ sí ilẹ̀ Israẹli
7 ǝmdi mana, Mǝn üstünggǝ ⱪolumni uzartip, seni ǝllǝrgǝ olja boluxⱪa tapxurimǝn; Mǝn seni hǝlⱪlǝr iqidin üzimǝn, mǝmlikǝtlǝr iqidin yoⱪitimǝn; Mǝn seni ⱨalak ⱪilimǝn; xuning bilǝn sǝn Mening Pǝrwǝrdigar ikǝnlikimni tonup yetisǝn.
nítorí náà, èmi yóò na ọwọ́ mi lé ọ, èmi yóò sì fi ọ fún àwọn aláìkọlà fún ìkógun. Èmi yóò sì gé ọ kúrò láàrín àwọn ènìyàn, èmi yóò sì jẹ́ kí o parun kúrò ni ilẹ̀ gbogbo. Èmi yóò sì pa ọ́ run, ìwọ yóò sì mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’”
8 Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Qünki Moab wǝ Seirning: «Yǝⱨuda pǝⱪǝt barliⱪ baxⱪa ǝllǝr bilǝn ohxax, halas» degini tüpǝylidin,
“Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí pé Moabu àti Seiri sọ wí pé, “Wò ó, ilé Juda ti dàbí gbogbo àwọn kèfèrí,”
9 xunga mana, Mǝn Moabning yenini — qegrasidiki xǝⱨǝrlǝrni, zeminining pǝhri bolƣan Bǝyt-Yǝximot, Baal-Meon wǝ Kiriatayim xǝⱨǝrliridin baxlap yerip aqimǝn;
nítorí náà, Èmi yóò ṣí Moabu sílẹ̀ láti àwọn ìlú gbogbo tí ó wà ní ààlà rẹ̀, ògo ilẹ̀ náà, Beti-Jeṣimoti, Baali-Meoni àti Kiriataimu.
10 ularni Ammoniylarning zemini bilǝn billǝ xǝrⱪtiki ǝllǝrgǝ tapxurimǝn; Mǝn Ammoniylarning yǝnǝ ǝllǝr arisida ǝslǝnmǝsliki üqün, ularning igidarliⱪiƣa tapxurimǝn;
Èmi yóò fi Moabu pẹ̀lú àwọn ará Ammoni lé àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn ní ìní, kí a má bà á lè rántí àwọn ará Ammoni láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.
11 wǝ Moab üstigǝ ⱨɵküm qiⱪirip jazalaymǝn; ular Mening Pǝrwǝrdigar ikǝnlikimni tonup yetidu.
Èmi yóò sì mú ìdájọ́ sẹ sí Moabu lára, wọn yóò sì mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’”
12 Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — qünki Edom Yǝⱨuda jǝmǝtidin ɵq elip yamanliⱪ ⱪilip, xuningdǝk eƣir gunaⱨkar bolƣini tüpǝylidin, intiⱪam alƣnini tüpǝylidin,
“Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí pé: ‘Nítorí pé Edomu gbẹ̀san lára ilé Juda, ó sì jẹ̀bi gidigidi nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀,
13 — ǝmdi Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Mǝn Edomƣa ⱪolumni sozimǝn; xuning bilǝn uni zeminidin adǝmlǝr ⱨǝm ⱨaywanlardin mǝⱨrum ⱪilimǝn; Mǝn uni Teman xǝⱨiridin tartip wǝyran ⱪilimǝn; ular Dedan xǝⱨirigiqǝ ⱪiliq bilǝn yiⱪilidu.
nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí pé: Èmi yóò na ọwọ́ mi sórí Edomu èmi yóò sì pa àwọn ènìyàn àti àwọn ẹranko rẹ̀. Èmi yóò fi ṣófo láti Temani dé Dedani yóò ti ipa idà ṣubú.
14 Xuning bilǝn Mǝn hǝlⱪim Israilning ⱪoli arⱪiliⱪ Edom üstidin Ɵz intiⱪamimni alimǝn; ular Mening aqqiⱪim ⱨǝm ⱪǝⱨrim boyiqǝ Edomda ix ⱪilidu; Edomiylar Mening intiⱪamimning nemǝ ikǝnlikini bilip yetidu, — dǝydu Rǝb Pǝrwǝrdigar.
Èmi yóò gbẹ̀san lára Edomu láti ọwọ́ àwọn ènìyàn mi Israẹli, wọn sì ṣe sí Edomu gẹ́gẹ́ bí ìbínú àti ìrunú mi, wọn yóò mọ̀ ìgbẹ̀san mi ní Olúwa Olódùmarè wí.’”
15 Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Filistiylǝr intiⱪam niyiti bilǝn ⱨǝrikǝt ⱪilip, kona ɵqmǝnliki bilǝn Yǝⱨudani yoⱪitayli dǝp iq-iqidin ɵq alƣini tüpǝylidin,
“Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí pé: ‘Nítorí tí àwọn ará Filistini hùwà ẹ̀san tí wọ́n sì gbẹ̀san pẹ̀lú odì ní ọkàn wọn, àti pẹ̀lú ìkórìíra gbangba àtijọ́ ní wíwá ọ̀nà láti pa Juda run,
16 Xunga Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Mana, Mǝn Filistiyǝning üstigǝ ⱪolumni uzartimǝn; Mǝn Kǝrǝtiylǝrni ⱪiriwetimǝn, dengiz boyidikilǝrning ⱪalduⱪlirinimu wǝyran ⱪilimǝn.
nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí pé, “Èmi ti ṣetán láti na ọwọ́ mi jáde sí àwọn ará Filistini, èmi yóò sì ké àwọn ará Kereti kúrò, èmi yóò sì pa àwọn tí ó kù ní etí kún run.
17 Mǝn ularning üstigǝ ⱪǝⱨrilik tǝnbiⱨlǝrni qüxürüp ⱪattiⱪ intiⱪam alimǝn; ularning üstidin intiⱪam alƣinimda ular Mening Pǝrwǝrdigar ikǝnlikimni tonup yetidu.
Èmi yóò sì gbẹ̀san ńlá lára wọn nípa ìbáwí gbígbóná; wọn yóò sì mọ̀ wí pé, Èmi ni Olúwa. Nígbà tí èmi yóò gba ẹ̀san lára wọn.”’”

< Əzakiyal 25 >