< Misirdin qiⱪix 6 >

1 Lekin Pǝrwǝrdigar Musaƣa: — Əmdi sǝn Mening Pirǝwngǝ ⱪilidiƣanlirimni kɵrisǝn; qünki u ⱪudrǝtlik bir ⱪoldin mǝjburlinip, ularni ⱪoyup beridu, ⱪudrǝtlik bir ⱪolning sǝwǝbidin ɵzining zeminidin ularni ⱪoƣlap qiⱪiriwetidu, — dedi.
Nígbà náà ní Olúwa sọ fún Mose pé, “Ní ìsin yìí, ìwọ yóò rí ohun tí èmi yóò ṣe sí Farao pẹ̀lú ọwọ́ agbára ńlá mi ni yóò fi jẹ́ kí wọn lọ; pẹ̀lú ọwọ́ agbára ńlá mi, òun yóò lé wọn jáde kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ̀.”
2 Andin Huda Musaƣa [yǝnǝ] sɵz ⱪilip mundaⱪ dedi: — Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn.
Ọlọ́run sì tún sọ fún Mose pé, “Èmi ni Olúwa.
3 Mǝn Ibraⱨimƣa, Isⱨaⱪⱪa wǝ Yaⱪupⱪa Ⱪadir-mutlǝⱪ Tǝngri süpitidǝ kɵründüm; lekin «Yaⱨwǝⱨ» degǝn namim bilǝn ularƣa axkara tonulmidim.
Mo fi ara hàn Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu bí Ọlọ́run alágbára, ṣùgbọ́n nípa orúkọ mi Olúwa, Èmi kò fi ara mi hàn wọ́n.
4 Mǝn ular bilǝn: — «Silǝr musapir bolup olturƣan zeminni, yǝni Ⱪanaan zeminini silǝrgǝ berimǝn» dǝp, ular bilǝn ǝⱨdǝ baƣlixip wǝdǝ ⱪilƣanmǝn.
Èmí sì tún fi ìdí májẹ̀mú mi múlẹ̀ pẹ̀lú wọn láti fún wọn ní ilẹ̀ Kenaani, ilẹ̀ tí wọn gbé gẹ́gẹ́ bí àjèjì.
5 Əmdi Mǝn misirliⱪlar ⱪul ⱪilip zulum salƣan Israillarning aⱨ-zarlirini anglap, ⱪilƣan xu ǝⱨdǝmni esimgǝ aldim.
Èmi sì ti tún gbọ́ kíkùn àwọn ọmọ Israẹli àwọn tí àwọn ará Ejibiti mú gẹ́gẹ́ bí ẹrú, àti pé èmi sì ti rántí májẹ̀mú mi.
6 Xunga Israillarƣa mundaⱪ degin: — «Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn; Mǝn Ɵzüm silǝrni misirliⱪlarning eƣir yükliri astidin qiⱪirip, ularning ⱪulluⱪidin azad ⱪilip, ⱪolumni uzitip ularƣa qong balayi’apǝtlǝrni qüxürüp, silǝrgǝ ⱨǝmjǝmǝt bolup ⱨɵrlükkǝ erixtürimǝn.
“Sọ fún àwọn ará ilé Israẹli, ‘Èmi ni Olúwa, Èmi yóò sọ yín di òmìnira kúrò nínú àjàgà àwọn ará Ejibiti. Èmi yóò sì gbà yín sílẹ̀ kúrò ní oko ẹrú wọn. Èmi yóò dá a yín sílẹ̀ pẹ̀lú apá nínà (àwọn iṣẹ́ ìyanu) àti pẹ̀lú ìdájọ́ ńlá.
7 Silǝrni Ɵz ⱪowmim boluxⱪa ⱪobul ⱪilimǝn wǝ Ɵzüm Hudayinglar bolimǝn; xuning bilǝn silǝr ɵzünglarni misirliⱪlarning yüklirining astidin ⱪutⱪuzup qiⱪarƣuqining Mǝn Hudayinglar Pǝrwǝrdigar ikǝnlikini bilisilǝr.
Èmi yóò mú un yín bí ènìyàn mi, èmi yóò sì jẹ́ Ọlọ́run yín. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ẹni tí ó mú un yín jáde kúrò nínú àjàgà àwọn ará Ejibiti.
8 Mǝn xuning bilǝn silǝrni ⱪol kɵtürüp Ibraⱨimƣa, Isⱨaⱪⱪa wǝ Yaⱪupⱪa berixkǝ ⱪǝsǝm ⱪilƣan zeminƣa elip barimǝn; Mǝn u yǝrni silǝrgǝ miras ⱪilip zeminliⱪⱪa berimǝn; Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn».
Èmi yóò mú un yín wá ilẹ̀ náà ti èmi ti búra pẹ̀lú ìgbọ́wọ́sókè láti fi fún Abrahamu. Isaaki àti Jakọbu. Èmi yóò fi fún un yín bí ohun ìní, Èmi ni Olúwa.’”
9 Bularning ⱨǝmmisini Musa Israillarƣa dǝp bǝrdi; lekin ular eƣir ⱪulluⱪ azabidin piƣanƣa qüxkǝn bolup, uningƣa ⱪulaⱪ salmidi.
Mose sì sọ èyí fún àwọn ará Israẹli, ṣùgbọ́n wọn kò fi etí sílẹ̀ sí Mose nítorí ọkàn wọn tó rẹ̀wẹ̀sì àti nítorí ìgbèkùn búburú bí ohun tí ó ti kọ́ sọ kó wọn sí ní oko ẹrú wọn.
10 Andin Pǝrwǝrdigar Musaƣa yǝnǝ: —
Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose.
11 Berip Misirning padixaⱨi Pirǝwngǝ: «Israillarning zeminingdin ketixigǝ yol ⱪoy», dǝp eytⱪin, dedi.
“Lọ, sọ fún Farao ọba Ejibiti pé kí ó jẹ́ kí àwọn ará Israẹli lọ kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ̀.”
12 Lekin Musa Pǝrwǝrdigarning aldida: Mana, Israillar manga ⱪulaⱪ salmiƣan yǝrdǝ, Pirǝwn ⱪandaⱪmu mǝndǝk kalpuki hǝtnǝ ⱪilinmiƣan bir adǝmgǝ ⱪulaⱪ salsun? — dedi.
Ṣùgbọ́n Mose sọ fún Olúwa pé, “Nígbà ti àwọn ará Israẹli tó jẹ́ ènìyàn mi kó fetí sí ọ̀rọ̀ mi, báwo ni Farao yóò ṣe fetí sí ọ̀rọ̀ mi, nígbà ti mo jẹ́ akólòlò?”
13 Əmma Pǝrwǝrdigar Musa wǝ Ⱨarunƣa sɵzlǝp, ularning Israillarƣa wǝ Misirning padixaⱨi Pirǝwngǝ Israillar toƣruluⱪ: — «Ular Misir zeminidin elip qiⱪirilsun» degǝn ǝmr yǝtküzüxini buyrudi.
Olúwa bá ìran Mose àti Aaroni sọ̀rọ̀ nípa àwọn ará Israẹli àti Farao ọba Ejibiti, ó pàṣẹ fún wọn pé kí wọn kó àwọn Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti.
14 Tɵwǝndikilǝr jǝmǝt baxliⱪliri: — Israilning tunji oƣli bolƣan Rubǝnning oƣulliri Ⱨanuⱪ, Pallu, Ⱨǝzron wǝ Karmi. Bular bolsa Rubǝnning nǝsilliri idi.
Wọ̀nyí ni olórí ìran wọn: àwọn ọmọ Reubeni àkọ́bí Israẹli ni: Hanoku, Pallu, Hesroni àti Karmi. Àwọn wọ̀nyí ni ìdílé Reubeni.
15 Ximeonning oƣulliri: — Yǝmuǝl, Yamin, Oⱨad, Yaⱪin, Zoⱨar wǝ ⱪanaanliⱪ ayaldin bolƣan Saullar idi; bular Ximeonning nǝsilliri idi.
Àwọn ọmọ Simeoni ni: Jemueli, Jamini, Ohadi, Jakini, Sohari àti Saulu ọmọ obìnrin Kenaani. Àwọn wọ̀nyí ni ìran Simeoni.
16 Lawiyning oƣullirining isimliri, nǝsǝbnamilirigǝ asasǝn: Gǝrxon, Koⱨat wǝ Mǝrari; Lawiyning ɵmrining yilliri bir yüz ottuz yǝttǝ yil boldi.
Ìwọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn: Gerṣoni, Kohati àti Merari. Lefi lo ẹ̀tàdínlógóje ọdún láyé.
17 Gǝrxonning oƣulliri aililiri boyiqǝ: — Libni wǝ Ximǝy.
Àwọn ọmọ Gerṣoni ni ìran wọn ni: Libni àti Ṣimei.
18 Koⱨatning oƣulliri: — Amram, Yizⱨar, Ⱨebron bilǝn Uzziǝl. Koⱨat bir yüz ottuz üq yil ɵmür kɵrdi.
Àwọn ọmọ Kohati ni: Amramu, Isari, Hebroni àti Usieli. Kohati lo ẹ̀tàléláádóje ọdún láyé.
19 Mǝrarining oƣulliri: — Maⱨli wǝ Muxi. Bular nǝsǝbnamiliri boyiqǝ Lawiyning nǝsilliri idi.
Àwọn ọmọ Merari ni: Mahili àti Muṣi. Ìwọ̀nyí ni ìran Lefi gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn.
20 Amram ɵz ⱨammisi Yokǝbǝdni hotunluⱪⱪa aldi, Yokǝbǝd uningƣa Ⱨarun wǝ Musani tuƣup bǝrdi. Amram bir yüz ottuz yǝttǝ yil ɵmür kɵrdi.
Amramu sì fẹ́ Jokebedi arábìnrin baba rẹ̀ ní ìyàwó. Jokebedi sì bí Aaroni àti Mose fún un. Amramu lo ẹ̀tàdínlógóje ọdún láyé.
21 Yizⱨarning oƣulliri: — Koraⱨ, Nǝfǝg wǝ Zikri idi.
Àwọn ọmọ Isari ni: Kora, Nefegi àti Sikri.
22 Uzziǝlning oƣulliri: — Mixaǝl, Əlzafan wǝ Sitri idi.
Àwọn ọmọ Usieli ni: Miṣaeli, Elsafani àti Sitiri.
23 Ⱨarun bolsa Naⱨxonning singlisini, yǝni Amminadabning ⱪizi Elixebani hotunluⱪⱪa aldi. U uningƣa Nadab bilǝn Abiⱨuni, wǝ Əliazar bilǝn Itamarni tuƣup bǝrdi.
Aaroni fẹ́ Eliṣeba ọmọbìnrin Amminadabu tí í ṣe arábìnrin Nahiṣoni, ó sì bí Nadabu, Abihu, Eleasari àti Itamari.
24 Koraⱨning oƣulliri: — Assir, Əlkanaⱨ wǝ Abi’asaf; bular Koraⱨlarning nǝsilliri idi.
Àwọn ọmọ Kora ni: Asiri, Elkana àti Abiasafu. Ìwọ̀nyí ni ìran Kora.
25 Ⱨarunning oƣli Əliazar Putiǝlning ⱪizlirining birini hotunluⱪⱪa aldi; u uningƣa Finiⱨasni tuƣup bǝrdi; bular bolsa ɵz nǝsǝbi boyiqǝ ⱨǝmmisi Lawiylarning jǝmǝt baxlⱪliri idi.
Eleasari ọmọ Aaroni fẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọbìnrin Putieli ní ìyàwó, ó sì bí Finehasi fún un. Ìwọ̀nyí ni olórí àwọn Lefi ni ìdílé ìdílé.
26 Pǝrwǝrdigarning: — Israillarni ⱪoxunlardǝk top-topi bilǝn Misir zeminidin elip qiⱪinglar, degǝn ǝmrini tapxuriwalƣuqilar dǝl muxu Ⱨarun bilǝn Musa idi.
Aaroni àti Mose yìí kan náà ni Olúwa sọ fún pé, “Ẹ kó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti ní ìsọ̀rí ìsọ̀rí.”
27 Israillar Misirdin qiⱪirilsun, dǝp Misirning padixaⱨi Pirǝwngǝ sɵz ⱪilƣanlar dǝl bu kixilǝr, yǝni muxu Musa bilǝn Ⱨarun idi.
Àwọn ni ó bá Farao ọba Ejibiti sọ̀rọ̀ nípa kíkó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni Ejibiti, àní Mose àti Aaroni yìí kan náà ni.
28 Pǝrwǝrdigar Misirning zeminida Musaƣa sɵz ⱪilƣan waⱪtida
Nígbà tí Olúwa bá Mose sọ̀rọ̀ ni Ejibiti,
29 Musaƣa: «Mǝn Pǝrwǝrdigardurmǝn. Sanga eytⱪinimning ⱨǝmmisini Misirning padixaⱨi Pirǝwngǝ degin», dǝp ǝmr ⱪildi.
Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Èmi ni Olúwa. Sọ ohun gbogbo ti mo ti sọ fún ọ fún Farao ọba Ejibiti.”
30 Lekin Musa Pǝrwǝrdigarning aldida: — Mǝndǝk kalpuki hǝtnǝ ⱪilinmiƣan bir kixigǝ Pirǝwn ⱪandaⱪmu ⱪulaⱪ salsun?» — dǝp jawap bǝrgǝnidi.
Ṣùgbọ́n Mose sì wí ní iwájú Olúwa pé, “Níwọ́n ìgbà ti mo jẹ́ akólòlò, ọ̀nà dà ti Farao yóò ṣe fi etí sí mi?”

< Misirdin qiⱪix 6 >