< Misirdin qiⱪix 34 >
1 Pǝrwǝrdigar Musaƣa: — Sǝn awwalⱪiƣa ohxax ɵzüng üqün taxtin ikki tahtayni yonup kǝl; Mǝn bu tahtaylarƣa sǝn ilgiri qeⱪiwǝtkǝn tahtaylardiki sɵzlǝrni yezip ⱪoyimǝn.
Olúwa sọ fún Mose pé, “E gé òkúta wàláà méjì jáde bí i ti àkọ́kọ́, Èmi yóò sì kọ àwọn ọ̀rọ̀ ìwé tó wà lára tí àkọ́kọ́ tí ìwọ ti fọ́ sára wọn.
2 Sǝn ǝtǝ ǝtigǝngiqǝ tǝyyar bolup, sǝⱨǝrdǝ Sinay teƣiƣa qiⱪip, xu yǝrdǝ taƣning qoⱪⱪisida Mening aldimda ⱨazir bolƣin.
Múra ní òwúrọ̀, kí o sì wá sórí òkè Sinai. Kí o fi ara rẹ hàn mí lórí òkè náà.
3 Lekin ⱨeq kixi sǝn bilǝn billǝ qiⱪmisun wǝ yaki taƣning ⱨeq yeridǝ baxⱪa adǝm kɵrünmisun, ⱪoy-kalilarmu taƣning tüwidǝ otlimisun, — dedi.
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ wá pẹ̀lú rẹ tàbí kí a rí wọn lórí òkè náà; bẹ́ẹ̀ ni agbo àgùntàn tàbí ọwọ́ ẹran kó má ṣe jẹ níwájú òkè náà.”
4 Musa awwalⱪiƣa ohxax taxtin ikki tahtayni yonup, ǝtisi tang sǝⱨǝr ⱪopup, bu ikki tax tahtayni ⱪolida elip, Pǝrwǝrdigarning buyruƣini boyiqǝ Sinay teƣiƣa qiⱪti.
Bẹ́ẹ̀ Mose sì gbẹ́ òkúta wàláà méjì bí ti àkọ́kọ́, ó sì gun orí òkè Sinai lọ ní kùtùkùtù òwúrọ̀, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pa á láṣẹ fún un; Ó sì gbé òkúta wàláà méjèèjì náà sí ọwọ́ rẹ̀.
5 Xuning bilǝn Pǝrwǝrdigar bulutta qüxüp, xu yǝrdǝ Musaning ⱪexida turup, «Yaⱨwǝⱨ» degǝn namini jakarlidi.
Nígbà náà ni Olúwa sọ̀kalẹ̀ nínú àwọsánmọ̀, ó sì dúró níbẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀, ó sì pòkìkí orúkọ Olúwa.
6 Pǝrwǝrdigar uning kɵz aldidin ɵtüp: — «Pǝrwǝrdigar, Pǝrwǝrdigar, rǝⱨimdil wǝ meⱨir-xǝpⱪǝtliktur, asan ƣǝzǝplǝnmǝydiƣan, xapaǝt bilǝn wapasi kǝng Tǝngridur,
Ó sì kọjá níwájú Mose, ó sì ń ké pé, “Olúwa, Olúwa, Ọlọ́run aláàánú àti olóore-ọ̀fẹ́, Ẹni tí ó lọ́ra láti bínú, tí ó pọ̀ ní ìfẹ́ àti olóòtítọ́,
7 mingliƣan-on mingliƣanlarƣa rǝⱨim-xapaǝt kɵrsitip, ⱪǝbiⱨlik, asiyliⱪ wǝ gunaⱨni kǝqürgüqidur; lekin u gunaⱨkarlarni ⱨǝrgiz gunaⱨsiz dǝp ⱪarimaydiƣan, bǝlki atilarning ⱪǝbiⱨlikining jazasini baliliri wǝ nǝwrlirigiqǝ, xundaⱪla üqinqi wǝ tɵtinqi ǝwladiƣiqǝ yüklǝydiƣan [Tǝngridur]» — dǝp jakarlidi.
Ẹni tí ó ń pa ìfẹ́ mọ́ fún ẹgbẹ̀rún, ó sì ń dáríjì àwọn ẹni búburú, àwọn ti ń ṣọ̀tẹ̀ àti ẹlẹ́ṣẹ̀. Síbẹ̀ kì í fi àwọn ẹlẹ́bi sílẹ̀ láìjìyà; Ó ń fi ìyà jẹ ọmọ àti àwọn ọmọ wọn fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba dé ìran kẹta àti ẹ̀kẹrin.”
8 Xuning bilǝn Musa dǝrⱨal yǝrgǝ bax ⱪoyup sǝjdǝ ⱪilip: —
Mose foríbalẹ̀ lẹ́ẹ̀kan náà ó sì sìn.
9 — Əy Rǝb, ǝgǝr mǝn rasttinla nǝziringdǝ iltipat tapⱪan bolsam, undaⱪta i Rǝb, arimizda biz bilǝn mangƣaysǝn; qünki bu hǝlⱪ dǝrwǝⱪǝ boyni ⱪattiⱪ bir hǝlⱪtur; bizning ⱪǝbiⱨlikimizni wǝ gunaⱨimizni kǝqürgǝysǝn, bizni Ɵz mirasing boluxⱪa ⱪobul ⱪilƣaysǝn! — dedi.
Ó wí pé, “Olúwa, bí èmi bá rí ojúrere rẹ, nígbà náà jẹ́ kí Olúwa lọ pẹ̀lú wa. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ènìyàn ọlọ́rùn líle ni wọn, dárí búburú àti ẹ̀ṣẹ̀ wa jì, kí o sì gbà wá gẹ́gẹ́ bí ìní rẹ.”
10 Xuning bilǝn u Musaƣa: — Mana, Mǝn bir ǝⱨdǝ tüzimǝn; sening barliⱪ hǝlⱪing aldida pütkül yǝr yüzining ⱨeqbir jayida yaki ⱨeqbir ǝl arisida ⱪilinip baⱪmiƣan mɵjizilǝrni yaritimǝn. Xuning bilǝn sǝn arisida bolƣan hǝlⱪingning ⱨǝmmisi Pǝrwǝrdigarning [karamǝt] ǝmǝlini kɵridu; qünki Mening silǝrgǝ ⱪilidiƣan ǝmǝlim dǝrwǝⱪǝ dǝⱨxǝtlik ix bolidu.
Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Èmi dá májẹ̀mú kan pẹ̀lú yín. Níwájú gbogbo ènìyàn rẹ Èmi yóò ṣe ìyanu, tí a kò tí ì ṣe ní orílẹ̀-èdè ní gbogbo ayé rí. Àwọn ènìyàn tí ìwọ ń gbé láàrín wọn yóò rí i bí iṣẹ́ tí Èmi Olúwa yóò ṣe fún ọ ti ní ẹ̀rù tó.
11 Mǝn bügün sanga tapilaydiƣan ǝmrlirimni tutⱪin; mana, Mǝn silǝrning aldinglardin Amoriy, Ⱪanaaniy, Ⱨittiy, Pǝrizziy, Ⱨiwiy wǝ Yǝbusiylarni ⱨǝydǝp qiⱪirimǝn.
Ṣe ohun tí Èmi pàṣẹ fún ọ lónìí. Èmi lé àwọn ará Amori, àwọn ará Kenaani, àwọn ará Peresi, àwọn ará Hiti, àwọn ará Hifi àti àwọn ará Jebusi jáde níwájú rẹ.
12 Əmdi ⱨezi bolƣinki, sǝn baridiƣan zeminda turuwatⱪanlar bilǝn ⱨeq ǝⱨdǝ baƣlaxmiƣin; bolmisa, bu ix silǝrgǝ tuzaⱪ bolidu;
Máa ṣọ́ra kí o má ba à bá àwọn ti ó n gbé ilẹ̀ náà tí ìwọ ń lọ dá májẹ̀mú, nítorí wọn yóò jẹ́ ìdẹwò láàrín rẹ.
13 bǝlki silǝr ularning ⱪurbangaⱨlirini qɵwüp, but tüwrüklirini sundurup, «axǝraⱨ» butlirini kesip taxlanglar.
Wó pẹpẹ wọn lulẹ̀, fọ́ òkúta mímọ́ wọn, kí o sì gé òpó Aṣerah wọn. (Ère òrìṣà wọn.)
14 Qünki sǝn ⱨeqⱪandaⱪ baxⱪa ilaⱨⱪa ibadǝt ⱪilmasliⱪing kerǝk — qünki Mǝnki Pǝrwǝrdigarning nami «Wapasizliⱪⱪa Ⱨǝsǝt Ⱪilƣuqi» bolup, ⱨǝsǝt ⱪilƣuqi bir ilaⱨdurmǝn.
Ẹ má ṣe sin ọlọ́run mìíràn, nítorí Olúwa, orúkọ ẹni ti ń jẹ́ Òjòwú, Ọlọ́run owú ni.
15 Bolmisa, xu zeminda turuwatⱪanlar bilǝn ǝⱨdǝ tüzüxüng mumkin; andin ular ilaⱨlirining kǝynidin yürüp buzuⱪqiliⱪ ⱪilip, ilaⱨliriƣa ⱪurbanliⱪlar ɵtküzginidǝ, silǝrni qaⱪirsa ularning ⱪurbanliⱪliridin yǝp ketixinglar mumkin;
“Máa ṣọ́ra kí ẹ má ṣe bá àwọn ènìyàn tí ń gbé ilẹ̀ náà dá májẹ̀mú; nígbà tí wọ́n bá ń ṣe àgbèrè tọ òrìṣà wọn, tí wọ́n sì rú ẹbọ sí wọn, wọn yóò pè yín, ẹ̀yin yóò sì jẹ ẹbọ wọn.
16 sǝn xundaⱪla yǝnǝ ularning ⱪizlirini oƣulliringƣa hotunluⱪⱪa elip berixing mumkin; u ⱪizlar ɵz ilaⱨlirining kǝynidin yürüp buzuⱪqiliⱪ ⱪilƣinida, ular oƣulliringnimu ɵz ilaⱨlirining arⱪisidin mangƣuzup, buzuⱪqiliⱪ ⱪilduruxi mumkin.
Nígbà tí ìwọ bá yàn nínú àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin rẹ ní ìyàwó, àwọn ọmọbìnrin wọ̀nyí yóò ṣe àgbèrè tọ òrìṣà wọn, wọn yóò sì mú kí àwọn ọmọkùnrin yín náà ṣe bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́.
17 Ɵzüng üqün ⱨeqⱪandaⱪ ⱪuyma butlarni yasatmiƣin.
“Ìwọ kò gbọdọ̀ dá ère òrìṣàkórìṣà fún ara rẹ.
18 Petir nan ⱨeytini tutunglar; Mening ǝmr ⱪilƣinimdǝk Abib eyida, bekitilgǝn waⱪitta yǝttǝ kün petir nan yǝnglar. Qünki silǝr Abib eyida Misirdin qiⱪⱪansilǝr.
“Àjọ àkàrà àìwú ni kí ìwọ máa pamọ́. Fún ọjọ́ méje ni ìwọ yóò jẹ àkàrà aláìwú, gẹ́gẹ́ bí Èmi ti pa á láṣẹ fún ọ. Ṣe èyí ní ìgbà tí a yàn nínú oṣù Abibu, nítorí ní oṣù náà ni ẹ jáde láti Ejibiti wá.
19 Baliyatⱪuning tunji mewisi Meningki bolidu; qarpay malliringning iqidin dǝslǝp tuƣulƣan ǝrkǝklǝr, kala bolsun, ⱪoy bolsun ularning tunjilirining ⱨǝmmisi Meningki bolsun.
“Gbogbo àkọ́bí inú kọ̀ọ̀kan tèmi ní i ṣe, pẹ̀lú àkọ́bí gbogbo ohun ọ̀sìn rẹ, bóyá ti màlúù tàbí ti àgùntàn.
20 Lekin exǝklǝrning tunji tǝhǝylirining orniƣa ⱪoza bilǝn bǝdǝl tɵlixing lazim bolidu. Əgǝr orniƣa [ⱪoza] bǝrmisǝng, tǝhǝyning boynini sunduruwǝtkin. Tunji oƣulliringni bolsa, ularƣa bǝdǝl tɵlǝp ⱪayturuwal. Ⱨeqkim Mening ⱨuzurumƣa ⱪuruⱪ ⱪol kǝlmisun.
Àkọ́bí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni kí ìwọ kí ó fi ọ̀dọ́-àgùntàn rà padà, ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá rà á padà, dá ọrùn rẹ̀. Ra gbogbo àkọ́bí ọkùnrin rẹ padà. “Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ wá síwájú mi ní ọwọ́ òfo.
21 Sǝn altǝ kün iqidǝ ix-ǝmǝlingni ⱪilip, yǝttinqi küni aram elixing zɵrür; yǝr ⱨǝydǝx waⱪti bolsun, orma waⱪti bolsun, aram elixing zɵrür.
“Ọjọ́ mẹ́fà ni ìwọ yóò ṣiṣẹ́, ṣùgbọ́n ní ọjọ́ keje ìwọ yóò sinmi; kódà ní àkókò ìfúnrúgbìn àti ní àkókò ìkórè ìwọ gbọdọ̀ sinmi.
22 Yengi buƣdayning tunji ⱨosulini tǝbriklǝydiƣan «ⱨǝptilǝr ⱨeyti»ni ɵtküzünglar; yilning ahirida «ⱨosul yiƣix ⱨeyti»ni ɵtküzünglar.
“Ṣe àjọ ọ̀sẹ̀ pẹ̀lú àkọ́so èso alikama àti àjọ ìkórè ní òpin ọdún.
23 Sening ⱨǝrbir ǝrkǝk kixiliring yilda üq ⱪetim Israilning Hudasi bolƣan Rǝb Pǝrwǝrdigarning aldiƣa ⱨazir bolsun.
Ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta lọ́dún, gbogbo àwọn ọkùnrin ni kí ó farahàn níwájú Olúwa Olódùmarè, Ọlọ́run Israẹli.
24 Qünki Mǝn taipilǝrni aldingdin ⱨǝydiwetip, qegraliringni kengǝytimǝn; xuningdǝk sǝn yilda üq ⱪetim Pǝrwǝrdigar Hudayingning aldiƣa ⱨazir boluxⱪa qiⱪip barsang, ⱨeqkim yeringgǝ kɵz ⱪirini salmaydu.
Èmi yóò lé orílẹ̀-èdè jáde níwájú rẹ, Èmi yóò sì mú kí ìpín rẹ fẹ̀, ẹnikẹ́ni kì yóò gba ilẹ̀ rẹ nígbà tí ìwọ bá gòkè lọ ní ìgbà mẹ́ta lọ́dún kọ̀ọ̀kan láti farahàn níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ.
25 Manga sunulidiƣan ⱪurbanliⱪning ⱪenini boldurulƣan nan bilǝn billǝ sunmiƣin; yaki ɵtüp ketix ⱨeytining ⱪurbanliⱪining gɵxini ǝtigǝ ⱪaldurma.
“Má ṣe ta ẹ̀jẹ̀ ẹbọ sí mi pẹ̀lú ohunkóhun tí ó bá ní ìwúkàrà, kí o má sì ṣe jẹ́ kí ẹbọ ìrékọjá kù títí di òwúrọ̀.
26 Zeminingning dǝslǝpki ⱨosulidin tunji mǝⱨsulatlarni Pǝrwǝrdigar Hudayingning ɵyigǝ kǝltürüp ata. Oƣlaⱪni anisining sütidǝ ⱪaynitip pixurma.
“Mú àkọ́ká èso ilẹ̀ rẹ tí ó dára jùlọ wá sí ilé Olúwa Ọlọ́run rẹ. “Ìwọ kò gbọdọ̀ bọ ọmọ ewúrẹ́ nínú omi ọmú ìyá rẹ̀.”
27 Pǝrwǝrdigar Musaƣa: — Bu sɵzlǝrni ɵzüng üqün yeziwalƣin; qünki Mǝn muxu sɵzlǝrni asas ⱪilip sǝn bilǝn wǝ Israil bilǝn ǝⱨdǝ baƣlidim, dedi.
Olúwa sì wí fún Mose pé, “Kọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí sílẹ̀, nítorí nípa àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ni Èmi bá ìwọ àti Israẹli dá májẹ̀mú.”
28 U waⱪitta Musa xu yǝrdǝ Pǝrwǝrdigarning ⱨuzurida ⱪiriⱪ keqǝ-kündüz turdi; u ⱨeqnǝrsǝ yemidi, ⱨeq su iqmidi. U yǝrdǝ [Pǝrwǝrdigar] tahtaylarƣa ǝⱨdining sɵzliri bolƣan on ǝmrni pütti.
Mose wà níbẹ̀ pẹ̀lú Olúwa fún ogójì ọ̀sán àti ogójì òru láìjẹ oúnjẹ tàbí mu omi. Ó sì kọ ọ̀rọ̀ májẹ̀mú náà òfin mẹ́wàá sára wàláà.
29 Musa Sinay teƣidin qüxkǝndǝ xundaⱪ boldiki (u taƣdin qüxkǝndǝ ikki ⱨɵküm-guwaⱨliⱪ tahtiyi uning ⱪolida idi), ɵzining [Pǝrwǝrdigar] bilǝn sɵzlǝxkini üqün yüzining parⱪirap kǝtkinini bilmǝytti.
Nígbà tí Mose sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè Sinai pẹ̀lú wàláà ẹ̀rí méjì ní ọwọ́ rẹ̀, òun kò mọ̀ pé ojú òun ń dán nítorí ó bá Olúwa sọ̀rọ̀.
30 Əmdi Ⱨarun wǝ barliⱪ Israillar Musani kɵrdi, mana, uning yüz terisi parⱪirap turatti; ular uningƣa yeⱪin berixtin ⱪorⱪuxti.
Nígbà tí Aaroni àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli rí Mose, ojú rẹ̀ ń dán, ẹ̀rù sì ń bà wọ́n láti súnmọ́ ọn.
31 Lekin Musa ularni qaⱪiriwidi, Ⱨarun wǝ jamaǝtning barliⱪ baxliri yenip, uning ⱪexiƣa kǝldi; Musa ular bilǝn sɵzlǝxti.
Ṣùgbọ́n Mose pè wọn; Aaroni àti gbogbo àwọn olórí àjọ padà wá bá a, ó sì bá wọn sọ̀rọ̀.
32 Xuningdin keyin, barliⱪ Israillar uning yeniƣa kǝldi; u waⱪitta Musa Pǝrwǝrdigar ɵzigǝ Sinay teƣida sɵz ⱪilƣinida tapxurƣan barliⱪ ǝmrlǝrni ularƣa tapilidi.
Lẹ́yìn èyí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli súnmọ́ ọn, ó sì fún wọn ní gbogbo àṣẹ tí Olúwa fún un lórí òkè Sinai.
33 Musa ularƣa dǝydiƣinini dǝp tügǝtti. U [sɵzligǝndǝ] yüzigǝ bir qümpǝrdǝ tartiwalƣanidi;
Nígbà tí Mose parí ọ̀rọ̀ sísọ fún wọn. Ó fi ìbòjú bo ojú rẹ̀.
34 Ⱪaqanki Musa Pǝrwǝrdigar bilǝn sɵzlixixkǝ uning ⱨuzuriƣa kirsǝ, qümpǝrdini eliwetǝtti, taki u yenip qiⱪⱪuqǝ xundaⱪ bolatti; yenip qiⱪⱪanda ɵzigǝ nemǝ tapilanƣan bolsa, xuni Israillarƣa eytip berǝtti.
Ṣùgbọ́n nígbàkígbà tí Mose bá wà níwájú Olúwa láti bá a sọ̀rọ̀, á ṣí ìbòjú náà títí yóò fi jáde. Nígbà tí ó bá sì jáde, á sì sọ fún àwọn ọmọ Israẹli ohun tí a ti pàṣẹ fún un,
35 Israillar Musaning yüz terisining parⱪirap turƣinini kɵrǝtti; xunga Musa yǝnǝ taki Pǝrwǝrdigar bilǝn sɵzlǝxkili uning ⱨuzuriƣa kirgüqǝ yüzigǝ qümpǝrdǝ tartiwalatti.
àwọn ọmọ Israẹli sì rí i pé ojú rẹ̀ ń dán. Mose á sì tún fi ìbòjú bo ojú rẹ̀ títí á fi lọ bá Olúwa sọ̀rọ̀.