< Ⱪanun xǝrⱨi 9 >

1 Angla, i Israil! Sǝn bügün ɵzüngdin qong wǝ küqlük ǝllǝrgǝ igǝ bolux üqün, sepilliri asmanƣa taⱪixidiƣan qong xǝⱨǝrlǝrni igilǝx üqün, Anakiylarni ⱪoƣlap qiⱪirix üqün Iordan dǝryasidin ɵtisǝn (sǝn ularni bilisǝn, ular toƣruluⱪ «kim Anakiylar aldida turalisun!» dǝp angliƣansǝn).
Gbọ́, ìwọ Israẹli. Báyìí, ẹ̀yin ti gbáradì láti la Jordani kọjá, láti lọ gba ilẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n tóbi, tí wọ́n sì lágbára jù yín lọ, tí wọ́n ní àwọn ìlú ńlá ńlá, tí odi wọn kan ọ̀run.
2
Àwọn ènìyàn náà lágbára wọ́n sì ga àní àwọn ọmọ Anaki ni wọ́n. Ẹ gbọ́ nípa wọn, ẹ sì gbọ́ tí àwọn ènìyàn ń sọ nípa wọn pé, “Ta ni ó le è dojú ìjà kọ àwọn ọmọ Anaki (òmíràn)?”
3 Sǝn bügünki kündǝ xuni bilip ⱪoyƣinki, sening aldingda mangƣuqi Pǝrwǝrdigar Hudayingning Ɵzidur, U yalmap yutⱪuqi ottur; u muxu ǝllǝrni ⱨalak ⱪilidu, aldingda ularni tezdin yiⱪitidu; sǝn ularning tǝwǝlikini igilǝp, Pǝrwǝrdigar sanga eytⱪandǝk ularni tezdin yoⱪitisǝn.
Ṣùgbọ́n kí ó dá a yín lójú lónìí pé Olúwa Ọlọ́run yín ni ó ń ṣáájú u yín lọ gẹ́gẹ́ bí iná ajónirun. Yóò jó wọn run, yóò sì tẹ orí wọn ba níwájú yín. Ẹ̀yin yóò sì lé wọ́n jáde, ẹ̀yin yóò sì run wọ́n kíákíá, bí Olúwa ti ṣèlérí fún un yín.
4 Pǝrwǝrdigar ularni aldingdin ⱨǝydigǝndǝ sǝn kɵnglüngdǝ: «Ⱨǝⱪⱪaniyliⱪim sǝwǝbidin Pǝrwǝrdigar meni zeminni igilǝx üqün uningƣa yetǝklǝp kirdi» demigin; bǝlki xu ǝllǝrning rǝzilliki tüpǝylidin Pǝrwǝrdigar sening aldingda ularni tǝǝlluⱪatidin mǝⱨrum ⱪilidu.
Lẹ́yìn tí Olúwa Ọlọ́run yín bá ti lé wọn jáde níwájú u yín, ẹ má ṣe wí fún ara yín pé, “Torí òdodo mi ní Olúwa ṣe mú mi wá síbí láti gba ilẹ̀ náà.” Rárá, ṣùgbọ́n nítorí ìwà búburú àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí ni Olúwa yóò ṣe lé wọn jáde níwájú u yín.
5 Sǝn ularning zeminiƣa kirip uni igilixing sening ⱨǝⱪⱪaniy bolƣanliⱪingdin yaki kɵnglüngning durusluⱪidin ǝmǝs, bǝlki bu ǝllǝrning rǝzillikidin wǝ Pǝrwǝrdigar ata-bowiliring Ibraⱨim, Isⱨaⱪ wǝ Yaⱪupⱪa ⱪǝsǝm ⱪilƣan sɵzigǝ ǝmǝl ⱪilix üqünmu Pǝrwǝrdigar Hudaying ularni sening aldingda tǝǝlluⱪatidin mǝⱨrum ⱪilidu.
Kì í ṣe nítorí òdodo yín, tàbí ìdúró ṣinṣin ni ẹ ó fi wọ ìlú wọn lọ láti gba ilẹ̀ wọn, ṣùgbọ́n nítorí ìwà búburú àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí ni Olúwa Ọlọ́run yín yóò fi lé wọn jáde kúrò níwájú u yín láti lè mú ohun tí ó búra fún àwọn baba ṣẹ: fún Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu.
6 Əmdi xuni bilip ⱪoyƣinki, Pǝrwǝrdigar Hudaying bu yahxi zeminni sanga miras ⱪilƣini sening ⱨǝⱪⱪaniyliⱪingdin ǝmǝs, qünki sǝn ǝsli boyni ⱪattiⱪ bir hǝlⱪsǝn.
Ṣùgbọ́n kí ó yé yín pé kì í ṣe nítorí òdodo yín ni Olúwa Ọlọ́run yín fi ń fún un yín ní ilẹ̀ rere náà, láti ní, nítorí pé ènìyàn ọlọ́rùn líle ni ẹ jẹ́.
7 Əmdi sening qɵl-bayawanda Pǝrwǝrdigar Hudayingni ⱪandaⱪ ƣǝzǝplǝndürgǝnlikingni esingdǝ tutⱪin — Uni untuma. Sǝn Misir zeminidin qiⱪⱪan kündin beri taki bu yǝrgǝ kǝlgüqǝ Pǝrwǝrdigarƣa asiyliⱪ ⱪilip kǝlding.
Ẹ rántí, ẹ má sì ṣe gbàgbé bí ẹ̀yin ti mú Olúwa Ọlọ́run yín bínú ní aginjù. Láti ọjọ́ ti ẹ tí kúrò ní Ejibiti ni ẹ̀yin ti ń ṣọ̀tẹ̀ sí Olúwa títí tí ẹ̀yin fi dé ìhín yìí.
8 Silǝr Ⱨorǝb teƣida Pǝrwǝrdigarni ƣǝzǝplǝndürgǝn wǝ Pǝrwǝrdigar silǝrgǝ aqqiⱪlinip, silǝrni ⱨalak ⱪilmaⱪqi boldi.
Ní Horebu ẹ̀yin ti mú kí Olúwa bínú, títí dé bi pé ó fẹ́ run yín.
9 Xu qaƣda mǝn tax tahtaylarni, yǝni Pǝrwǝrdigar silǝr bilǝn tüzgǝn ǝⱨdǝ tahtaylirini tapxuruwelix üqün taƣⱪa qiⱪⱪanidim; mǝn taƣda ⱪiriⱪ keqǝ-kündüz turdum (mǝn nǝ tamaⱪ yemidim, nǝ su iqmidim);
Nígbà tí mo gòkè lọ láti lọ gba wàláà òkúta, wàláà májẹ̀mú ti Olúwa ti bá a yín dá. Ogójì ọ̀sán àti òru ni mo fi wà lórí òkè náà, èmi kò fẹnu kan oúnjẹ bẹ́ẹ̀ ni ń kò mu omi.
10 Xuning bilǝn Pǝrwǝrdigar manga Ɵz barmiⱪi bilǝn pütkǝn ikki tahtayni tapxurdi; ularda Pǝrwǝrdigar taƣda ot iqidǝ silǝrgǝ sɵzligǝn qaƣda, jamaǝt yiƣilƣan küni eytⱪan barliⱪ sɵzlǝr pütülgǝnidi.
Olúwa fún mi ní wàláà òkúta méjì tí a fi ìka Ọlọ́run kọ. Lórí wọn ni a kọ àwọn òfin tí Ọlọ́run sọ fún un yín lórí òkè láàrín iná, ní ọjọ́ ìpéjọpọ̀ sí.
11 Wǝ xundaⱪ boldiki, ⱪiriⱪ keqǝ-kündüz ɵtüp, Pǝrwǝrdigar manga ikki tax tahtay, yǝni ǝⱨdǝ tahtaylirini bǝrdi.
Lópin ogójì ọ̀sán àti òru wọ̀nyí, Olúwa fún mi ní sílétì òkúta méjì, wàláà òkúta májẹ̀mú náà.
12 Wǝ Pǝrwǝrdigar manga: «Ornungdin turƣin, muxu yǝrdin qüxkin; qünki sǝn Misirdin qiⱪarƣan hǝlⱪing ɵzlirini bulƣidi; ular tezla Mǝn ularƣa tapiliƣan yoldin qǝtnǝp ɵzlirigǝ ⱪuyma bir butni yasidi» dedi.
Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa sọ fún mi pé, “Sọ̀kalẹ̀ kúrò níhìn-ín kíákíá, torí pé àwọn ènìyàn rẹ tí o mú jáde láti Ejibiti ti hùwà ìbàjẹ́. Wọ́n ti yípadà kúrò, nínú ọ̀nà mi, wọ́n sì ti ṣe ère dídá fún ara wọn.”
13 Pǝrwǝrdigar manga sɵz ⱪilip: «Mǝn bu hǝlⱪni kɵrüp yǝttim; mana, u boyni ⱪattiⱪ bir hǝlⱪtur.
Olúwa sì sọ fún mi pé, “Mo ti rí àwọn ènìyàn wọ̀nyí pé ènìyàn ọlọ́rùn líle gbá à ni wọ́n.
14 Meni tosma, Mǝn ularni yoⱪitimǝn, ularning namini asmanning tegidin ɵqürüwetimǝn wǝ xundaⱪ ⱪilip, seni ulardin qong wǝ uluƣ bir hǝlⱪ ⱪilimǝn» — dedi.
Fi mí sílẹ̀, jẹ́ kí n run wọ́n, kí n sì pa orúkọ wọn rẹ́ kúrò lábẹ́ ọ̀run. Èmi yóò sì sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè tí ó lágbára tí ó sì pọ̀jù wọ́n lọ.”
15 Mǝn burulup, taƣdin qüxtüm; taƣ bolsa ot bilǝn yalⱪunlawatatti; ikki ǝⱨdǝ tahtiyi ikki ⱪolumda idi.
Báyìí ni mo yípadà, tí mó sì sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè náà wá, orí òkè tí o ń yọ iná. Àwọn wàláà májẹ̀mú méjèèjì sì wà lọ́wọ́ mi.
16 Mǝn kɵrdüm, mana silǝr Pǝrwǝrdigar Hudayinglar aldida gunaⱨ ⱪilipsilǝr; silǝr ɵzünglar üqün ⱪuyma bir mozayni yasapsilǝr; silǝr tezla Pǝrwǝrdigar silǝrgǝ tapiliƣan yoldin qǝtnǝp ketipsilǝr.
Ìgbà tí mo ṣàkíyèsí, mo rí i pé ẹ ti dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run yín. Ẹ ti ṣe ère òrìṣà ní ìrí ọ̀dọ́ màlúù, fún ara yín. Ẹ ti yípadà kánkán kúrò nínú ọ̀nà tí Olúwa ti pàṣẹ fún un yín.
17 Mǝn ikki tahtayni ikki ⱪolumƣa elip, qɵrüp taxlap, ularni kɵz aldinglarda qeⱪiwǝttim.
Bẹ́ẹ̀ ni mó ju wàláà méjèèjì náà mọ́lẹ̀, mo sì fọ́ wọn sí wẹ́wẹ́ lójú u yín.
18 Silǝr Pǝrwǝrdigarni ƣǝzǝplǝndürüp barliⱪ ɵtküzgǝn gunaⱨinglar, yǝni Pǝrwǝrdigarning nǝziridǝ rǝzil bolƣanni ⱪilƣininglar üqün, yǝnǝ awwalⱪidǝk Pǝrwǝrdigar aldida yiⱪilip, ⱪiriⱪ keqǝ-kündüz düm yattim (mǝn ⱨeq nǝrsǝ yemidim, su iqmidim)
Lẹ́yìn náà mo tún wólẹ̀ níwájú Olúwa fún ogójì ọ̀sán àti ogójì òru, èmi kò jẹ oúnjẹ kankan bẹ́ẹ̀ ni èmi kò mu omi, nítorí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí ẹ tí dá, tí ẹ sì ń ṣe búburú lójú Olúwa, tí ẹ sì ń mú u bínú.
19 qünki mǝn Pǝrwǝrdigarning silǝrni yoⱪitidiƣan ⱪattiⱪ ƣǝzipi ⱨǝm ⱪǝⱨridin ⱪorⱪtum. Pǝrwǝrdigar xu qaƣdimu mening tilikimni anglidi.
Mo bẹ̀rù ìbínú àti ìrunú Olúwa, nítorí pé inú bí i sí i yín dé bi wí pé ó fẹ́ pa yín run. Ṣùgbọ́n Olúwa tún fetí sí mi lẹ́ẹ̀kan sí i.
20 Pǝrwǝrdigar Ⱨarundin ƣǝzǝplinip, unimu yoⱪatmaⱪqi boldi; mǝn Ⱨarun üqünmu dua ⱪildim.
Inú sì bí Olúwa sí Aaroni láti pa á run, nígbà náà ni mo tún gbàdúrà fún Aaroni náà.
21 Mǝn silǝrning gunaⱨinglarni, yǝni yasiƣan mozayni elip uni otta kɵydürdüm wǝ uni yanjip kukum-talⱪan ⱪilip eziwǝttim; uning topisini elip taƣdin qüxidiƣan eriⱪ süyigǝ qeqiwǝttim
Bẹ́ẹ̀ ni mo sì mú ohun tí ó mú un yín dẹ́ṣẹ̀, àní ère ẹgbọrọ màlúù tí ẹ ti ṣe, mo sì fi iná sun ún, bẹ́ẹ̀ ni mo gún un, mo sì lọ̀ ọ́ lúúlúú bí eruku lẹ́búlẹ́bú, mo sì da ẹ̀lọ̀ rẹ̀ sínú odò tí ń sàn nísàlẹ̀ òkè.
22 (silǝr yǝnǝ Tabǝraⱨ, Massaⱨ, Kibrot-Ⱨattawaⱨdimu Pǝrwǝrdigarni ƣǝzǝplǝndürdünglar.
Ẹ̀yin tún mú Olúwa bínú ní Tabera, Massa àti ní Kibirotu-Hattaafa.
23 Pǝrwǝrdigar silǝrni Ⱪadǝx-Barneadin [Ⱪanaanƣa] mangdurmaⱪqi bolup silǝrgǝ: «Qiⱪip, Mǝn silǝrgǝ tǝⱪdim ⱪilƣan zeminni igilǝnglar» — degǝndimu, silǝr Uning sɵzigǝ ⱪarxi qiⱪip asiyliⱪ ⱪildinglar, nǝ Uningƣa ixǝnmidinglar, nǝ awaziƣa ⱨeq ⱪulaⱪ salmidinglar.
Nígbà tí Olúwa ran an yín jáde ní Kadeṣi-Barnea, Ó wí pé, “Ẹ gòkè lọ, kí ẹ sì gba ilẹ̀ náà tí mo fi fún un yín.” Ṣùgbọ́n ẹ ṣọ̀tẹ̀ sí òfin Olúwa Ọlọ́run yín. Ẹ kò gbẹ́kẹ̀lé e, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọ́ tirẹ̀.
24 Mǝn silǝrni tonuƣan kündin tartip silǝr Pǝrwǝrdigar Hudayinglarƣa asiyliⱪ ⱪilip kǝldinglar).
Láti ìgbà tí mo ti mọ̀ yín ni ẹ ti ń ṣọ̀tẹ̀ sí Olúwa.
25 Xuning bilǝn mǝn axu qaƣda Pǝrwǝrdigar aldida ɵzümni yǝrgǝ etip yǝnǝ ⱪiriⱪ keqǝ-kündüz düm yattim; dǝrwǝⱪǝ düm yattim; qünki Pǝrwǝrdigar silǝrgǝ ⱪarap «ularni yoⱪitimǝn» degǝnidi.
Mo ti wólẹ̀ níwájú Olúwa fún ogójì ọ̀sán àti òru wọ̀nyí nítorí pé Olúwa sọ pé Òun yóò pa yín run.
26 Xunga mǝn Pǝrwǝrdigarƣa dua ⱪilip: «I Rǝb Pǝrwǝrdigar, Sǝn Ɵz uluƣluⱪung arⱪiliⱪ Ɵzüng üqün ⱨɵrlük bǝdili tɵlǝp setiwalƣan, Misirdin küqlük ⱪolung bilǝn qiⱪarƣan Ɵz hǝlⱪing bolƣan mirasingni yoⱪatmiƣaysǝn;
Mo gbàdúrà sí Olúwa wí pé, “Olúwa Olódùmarè, má ṣe run àwọn ènìyàn rẹ, àní ogún rẹ tí o ti rà padà, nípa agbára rẹ tí o sì fi agbára ńlá mú wọn jáde láti Ejibiti wá.
27 Ɵz ⱪulliring Ibraⱨim, Isⱨaⱪ wǝ Yaⱪupni esingdǝ tutⱪaysǝn; bu hǝlⱪning baxbaxtaⱪliⱪiƣa, ularning rǝzilliki yaki gunaⱨiƣa ⱪarimiƣaysǝn;
Rántí àwọn ìránṣẹ́ rẹ Abrahamu, Isaaki, àti Jakọbu. Fojú fo orí kunkun àwọn ènìyàn yìí, pẹ̀lú ìwà búburú àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
28 bolmisa, sǝn bizni elip qiⱪⱪan xu zemindikilǝr: «Pǝrwǝrdigar bu hǝlⱪni ularƣa wǝdǝ ⱪilƣan zeminni igilǝxkǝ elip kirǝlmǝydiƣanliⱪi üqün wǝ ularƣa nǝprǝtlǝngini tüpǝylidin ularni qɵl-bayawanda yoⱪitixⱪa [Misirdin] qiⱪardi» — dǝydu.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, orílẹ̀-èdè tí ìwọ ti mú wa jáde wá yóò wí pé, ‘Torí pé Olúwa kò lè mú wọn lọ sí ilẹ̀ náà tí ó ti ṣèlérí fún wọn, àti pé ó ti kórìíra wọn, ni ó fi mú wọn jáde láti pa wọ́n ní aginjù.’
29 Ⱪandaⱪla bolmisun, ular zor küqüng wǝ uzartilƣan biliking bilǝn [Misirdin] qiⱪarƣan hǝlⱪing wǝ sening mirasingdur» — dedim.
Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn rẹ ni wọ́n, ogún rẹ tí o ti fi ọwọ́ agbára rẹ àti nínà ọwọ́ rẹ mú jáde.”

< Ⱪanun xǝrⱨi 9 >