< Yeremiya 24 >

1 Babil padishahi Néboqadnesar Yérusalémdin Yehoakimning oghli, Yehuda padishahi Yekoniyah, Yehuda emir-shahzadiliri, hünerwenler we tömürchilerni esirge élip Babilgha sürgün qilghandin kéyin, Perwerdigar manga Öz ibadetxanisi aldidiki ikki séwet enjürni «mana kör» dep körsetken.
Lẹ́yìn tí Nebukadnessari ọba Babeli ti kó Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn oníṣọ̀nà àti oníṣẹ́ ọwọ́ ti Juda lọ sí ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí ilẹ̀ àjèjì Babeli tán. Olúwa fi agbọ̀n èso ọ̀pọ̀tọ́ méjì hàn mí tí a gbé sí iwájú pẹpẹ Olúwa.
2 Bir séwette deslepki pishqan enjürdek intayin yaxshi enjürler bar idi; ikkinchi séwette yégili bolmaydighan, intayin nachar enjürler bar idi.
Agbọ̀n kan ni èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó dára bí èyí tí ó tètè pọ́n; èkejì sì ní èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó burú rékọjá tí kò sì le è ṣe é jẹ.
3 Andin Perwerdigar manga: «Néme kördüng, Yeremiya?» — dep soridi. Men: «Enjürlerni kördüm; yaxshiliri bolsa intayin yaxshiken; nacharliri yégili bolmaydighan, intayin nachar iken» — dédim.
Nígbà náà ni Olúwa bi mí pé, “Kí ni ìwọ rí Jeremiah?” Mo dáhùn pe, “Èso ọ̀pọ̀tọ́.” Mo dáhùn. “Èyí tí ó dáradára púpọ̀, ṣùgbọ́n èyí tí ó burú burú rékọjá tí kò sì ṣe é jẹ.”
4 Perwerdigarning sözi manga kélip mundaq déyildi: —
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
5 Israilning Xudasi bolghan Perwerdigar mundaq deydu: — Men Yehudadin sürgün bolghanlarni, yeni Méning bu yerdin kaldiylerning zéminigha ewetkenlirimni bu yaxshi enjürlerdek yaxshi dep qaraymen;
“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Gẹ́gẹ́ bí àwọn èso ọ̀pọ̀tọ́ dáradára yìí ni Èmi yóò ka àwọn tí wọ́n lọ sí ilẹ̀ àjèjì láti Juda sí tí èmi rán jáde kúrò ní ibí yìí lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kaldea.
6 Men ulargha yaxshi bolsun dep közümni ulargha tikimen we ularni bu zémin’gha qayturimen; Men ularni ghulitip tashlimaymen, belki ularni qurimen; ularni yulup tashlimaymen, belki tikip östürimen.
Ojú mi yóò máa ṣọ́ wọn lọ fún rere, Èmi yóò gbé wọn ró, n kò ní já wọn lulẹ̀. Èmi yóò gbìn wọ́n, n kò sì ní fà wọ́n tu.
7 Men ulargha Méning Perwerdigar ikenlikimni bilidighan, Méni tonuydighan bir qelbni teqdim qilimen; shuning bilen ular Méning xelqim bolidu, Men ularning Xudasi bolimen; chünki ular pütün qelbi bilen yénimgha qaytidu.
Èmi yóò fún wọn ní ọkàn láti mọ̀ mí pé, “Èmi ni Olúwa.” Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi; Èmi ni yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn; nítorí pé wọn yóò padà sọ́dọ̀ mi pẹ̀lú gbogbo ọkàn wọn.
8 Lékin nachar enjürler, yeni yégili bolmaydighan, intayin nachar enjürler qandaq bolghan bolsa, — deydu Perwerdigar, — Berheq, Men Yehuda padishahi Zedekiyani, emir-shahzadilirini we Yérusalémdikilerning qalghan qismini, bu zéminda qalghanlarni we Misirda turuwatqanlarni shuninggha oxshash qilimen;
“‘Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí èso ọ̀pọ̀tọ́ tí kò dára, tí ó burú tí kò ṣe é jẹ,’ ni Olúwa wí, ‘bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe pẹ̀lú Sedekiah ọba Juda, àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn tí ó yẹ ní Jerusalẹmu, yálà wọ́n wà lórí ilẹ̀ yìí tàbí wọ́n ń gbé Ejibiti.
9 Men ularni yer yüzidiki barliq padishahliqlargha wehime salghuchi bir obyékt bolushqa, külpetke chüshüshke tapshurimen; men ularni heydiwetken barliq jaylarda ularni reswachiliqning obyékti, söz-chöchek, tapa-tenining obyékti we lenet sözliri bolushqa tapshurimen.
Èmi yóò sọ wọ́n di ìwọ̀sí àti ẹni ibi nínú gbogbo ìjọba ayé, láti di ẹni ìfibú àti ẹni òwe, ẹni ẹ̀sín, àti ẹni ẹ̀gàn ní ibi gbogbo tí Èmi ó lé wọn sí.
10 Men ulargha hem ata-bowilirigha teqdim qilghan zémindin yoqitilghuche ular arisigha qilich, qehetchilik we wabani ewetimen.
Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn sí wọn, títí tí gbogbo wọn yóò parun lórí ilẹ̀ tí a fún wọn àti fún àwọn baba wọn.’”

< Yeremiya 24 >