< Nnwom 87 >

1 Koramma dwom. Wato ne fapem wɔ bepɔw kronkron no so;
Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
2 Awurade dɔ Sion apon no sen Yakob atenae nyinaa.
Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
3 Wɔka wo ho anuonyamsɛm Onyankopɔn kuropɔn:
Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
4 “Mede Rahab ne Babilonia bɛka wɔn a wɔyɛ osetie ma me no ho, Filistia, Tiro ne Kus nso na maka se, ‘Wɔwoo eyinom wɔ Sion.’”
“Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
5 Ampa ara wɔbɛka afa Sion ho se, “Wɔwoo oyi ne ɔno wɔ no mu, na Ɔsorosoroni no ankasa de no betim hɔ.”
Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
6 Awurade bɛkyerɛw wɔ nnipa dinkyerɛw nhoma no mu se, “Wɔwoo oyi wɔ Sion.”
Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
7 Na wɔbɛto dwom se, “Me ntin nyinaa wɔ wo mu.”
Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”

< Nnwom 87 >