< Nnwom 20 >

1 Dawid dwom. Awurade ntie wo wɔ wʼahohia mu; Yakob Nyankopɔn din mmɔ wo ho ban.
Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Kí Olúwa kí ó gbóhùn rẹ ní ọjọ́ ìpọ́njú; kí orúkọ Ọlọ́run Jakọbu kí ó dáàbò bò ọ́.
2 Ɔmfa mmoa mfi kronkronbea hɔ mmrɛ wo, na omfi Sion mmɛhyɛ wo den.
Kí ó rán ìrànlọ́wọ́ sí ọ, láti ibi mímọ́ kí ó sì tì ọ́ lẹ́yìn láti Sioni wá.
3 Ɔnkae wʼafɔrebɔ nyinaa, na ɔmma wo hyew afɔre nsɔ nʼani.
Kí ó sì rántí gbogbo ẹbọ rẹ kí ó sì gba ẹbọ sísun rẹ. (Sela)
4 Ɔmma wo nea wo koma pɛ, na wo nhyehyɛe nyinaa nyɛ yiye.
Kí ó fi fún ọ gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ kí ó sì mú gbogbo ìmọ̀ rẹ ṣẹ.
5 Yɛbɛbɔ ose bere a woadi nkonim, na yɛama yɛn frankaa so wɔ yɛn Nyankopɔn din mu. Awurade nyɛ wʼabisade nyinaa mma wo.
Àwa yóò hó fún ayọ̀ nígbà tí o bá di aṣẹ́gun àwa yóò gbé àsíá wa sókè ní orúkọ Ọlọ́run wa. Kí Olúwa kí ó mú gbogbo ìbéèrè rẹ̀ ṣẹ.
6 Afei mahu sɛ Awurade ma nea wasra no no nkonimdi, ofi ne kronkronbea wɔ ɔsoro gye no so, ɔde ne nkonimdi tumi a ɛwɔ ne nsa nifa mu no.
Nísinsin yìí, èmi mọ̀ wí pé, Olúwa pa ẹni àmì òróró rẹ̀ mọ́. Yóò gbọ́ láti ọ̀run mímọ́ rẹ̀ wá pẹ̀lú agbára ìgbàlà ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
7 Ebinom de wɔn ho to wɔn nteaseɛnam so na afoforo nso, wɔn apɔnkɔ so, nanso yɛn de, yɛde yɛn ho to Awurade yɛn Nyankopɔn din so.
Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé kẹ̀kẹ́, àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé ẹṣin, ṣùgbọ́n àwa gbẹ́kẹ̀lé orúkọ Olúwa Ọlọ́run wa.
8 Wɔbrɛ wɔn ase ma wɔhwehwe ase, na yɛn de, yɛsɔre gyina kirebenn.
Wọ́n wólẹ̀, ní eékún, wọ́n sì ṣubú, ṣùgbọ́n àwa dìde, a sì dúró ṣinṣin.
9 Awurade, ma ɔhene nkonimdi! Yɛfrɛ a, gye yɛn so! Wɔde ma dwonkyerɛfo.
Olúwa, fi ìṣẹ́gun fún ọba! Dá wa lóhùn nígbà tí a bá ń kígbe pè!

< Nnwom 20 >