< Yeremia 2 >

1 Awurade asɛm baa me so:
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé:
2 “Kɔpae mu ka ma Yerusalem nte: “‘Mekae sɛnea wode wo ho maa me wo mmabun bere mu, sɛnea wodɔɔ me wɔ wʼayeforo bere mu na wudii mʼakyi wɔ sare so, asase a wonnuaa hwee wɔ so no.
“Lọ kí o sì kéde sí etí Jerusalẹmu pé: “Báyìí ni Olúwa wí, “‘Èmi rántí ìṣeun ìgbà èwe rẹ, ìfẹ́ ìgbéyàwó rẹ àti nígbà tí ìwọ tẹ̀lé mi nínú ijù, nínú ìyàngbẹ ilẹ̀.
3 Na Israel yɛ kronkron ma Awurade, ne twabere mu aduankan; wɔn a wodii nʼani no wobuu wɔn fɔ, na amanehunu baa wɔn so,’” sɛnea Awurade, se ni.
Israẹli jẹ́ mímọ́ sí Olúwa, àkọ́kọ́ èso ìkórè rẹ̀, gbogbo ẹnikẹ́ni tí ó jẹ run ni a ó dá lẹ́bi, ibi yóò sì wá sí orí wọn,’” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí.
4 Muntie Awurade asɛm, mo Yakob asefo, mo Israel mmusuakuw nyinaa.
Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin ìdílé Jakọbu àti gbogbo ẹ̀yin ará ilé Israẹli.
5 Eyi ne nea Awurade se: “Mfomso bɛn na mo agyanom huu wɔ me ho a ɛma wɔtwee wɔn ho kɔɔ akyirikyiri sɛɛ? Wodii ahoni a wɔn so nni mfaso akyi, maa wɔn ankasa bɛyɛɛ ahuhufo.
Báyìí ni Olúwa wí: “Irú àìṣedéédéé wo ni baba yín rí lọ́wọ́ mi, tí wọ́n fi jìnnà sí mi? Wọ́n tẹ̀lé àwọn òrìṣà asán, àwọn fúnra wọn sì di asán.
6 Wɔammisa se, ‘Ɛhe na Awurade wɔ? Nea oyii yɛn fii Misraim na ɔde yɛn faa sare wosee so, nweatam ne abonabon asase a awo na ayɛ owubon no. Asase a obiara mfa so na obiara nte so no.’
Wọn kò béèrè, ‘Níbo ni Olúwa wà, tí ó mú wa jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá, tí ó mú wa la aginjù já, tí ó mú wa la àárín pẹ̀tẹ́lẹ̀ àti ihò, ìyàngbẹ ilẹ̀ àti òkùnkùn biribiri, ilẹ̀ ibi tí ẹnikẹ́ni kò là kọjá, tí ẹnikẹ́ni kò sì tẹ̀dó sí?’
7 Mede mo beduaa asasebere so sɛ munni so nnuaba ne ɛso nnepa. Nanso mubeguu mʼasase ho fi, na moyɛɛ mʼagyapade akyiwade.
Èmi mú yín wá sí ilẹ̀ ọlọ́ràá láti máa jẹ èso ibẹ̀ àti ọrọ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀yin wọ inú rẹ̀, ẹ sì bà á jẹ́, ẹ sì sọ ogún mi di ohun ìríra.
8 Asɔfo no ammisa se, ‘Ɛhe na Awurade wɔ?’ Wɔn a wɔde mmara yɛ adwuma no anhwehwɛ me; ntuanofo sɔre tiaa me. Adiyifo no de Baal hyɛɛ nkɔm, na wodii ahoni huhuw akyi.
Àwọn àlùfáà kò béèrè wí pé, ‘Níbo ni Olúwa wà?’ Àwọn tí ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú òfin kò si mọ̀ mí, àwọn olùṣọ́ sì ṣẹ̀ sí mi. Àwọn wòlíì sì ń sọtẹ́lẹ̀ nípa òrìṣà Baali, wọ́n sì ń tẹ̀lé àwọn òrìṣà asán.
9 “Ɛno nti, merebɔ mo kwaadu bio,” nea Awurade se ni. “Na mɛbɔ mo mma mma kwaadu.
“Nítorí náà, mo fi ẹ̀sùn kàn yín lẹ́ẹ̀kan sí i,” ni Olúwa wí. “Èmi ó sì fi ẹ̀sùn kan àwọn ọmọ ọwọ́ rẹ.
10 Muntwa nkɔ Kitim mpoano nkɔhwɛ, monsoma nkɔ Kedar nkɔhwehwɛ mu yiye; monhwɛ sɛ biribi a ɛte sɛɛ asi wɔ hɔ:
Rékọjá lọ sí erékùṣù àwọn ara Kittimu, kí ẹ sì wò ó, ránṣẹ́ lọ sí ìlú Kedari, kí ẹ sì kíyèsi gidigidi; kí ẹ wò bí irú nǹkan báyìí bá ń bẹ níbẹ̀?
11 Ɔman bi asesa wɔn anyame pɛn ana? Nso wɔnnyɛ anyame mpo. Nanso me nkurɔfo de wɔn anuonyam asesa ahoni huhuw.
Orílẹ̀-èdè kan ha á pa ọlọ́run rẹ̀ dà? (Síbẹ̀, wọ́n kì í ṣe iṣẹ́ ọlọ́run.) Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi ti pààrọ̀ Ọlọ́run ògo wọn fún àwọn ère tí kò níyì.
12 Mo ɔsorosoro, momma mo ho nnwiriw mo wɔ eyi ho, na mo ho nwosow wɔ akomatu mu,” nea Awurade se ni.
Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì kí ẹ sì wárìrì pẹ̀lú ìbẹ̀rù ńlá,” ni Olúwa wí.
13 “Me nkurɔfo ayɛ bɔne ahorow abien: Wɔapa me, me a meyɛ nkwa asubura no, na wɔatutu wɔn ankasa mmura amoa, mmura a apaapae a entumi nkora nsu.
“Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì, wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀, Èmi orísun omi ìyè, wọ́n sì ti ṣe àmù, àmù fífọ́ tí kò lè gba omi dúró.
14 Israel yɛ akoa anaa ɔsomfo fi awo mu ana? Adɛn nti na wayɛ asade yi?
Israẹli ha á jẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀ ẹrú nípa ìbí? Kí ló ha a dé tí ó fi di ìkógun?
15 Gyata abobɔ mu; wɔaworo so akyerɛ no. Wɔama nʼasase ada mpan; wɔahyehyew ne nkurow ayɛ no amamfo.
Àwọn kìnnìún ké ramúramù; wọ́n sì ń bú mọ́ wọn. Wọ́n ti fi ilẹ̀ rẹ̀ ṣòfò; ìlú rẹ̀ ti di jíjóná, ó sì ti di ìkọ̀sílẹ̀.
16 Afei Memfis ne Tapanhes mmarima ayi wo ti so nwi.
Bákan náà, àwọn ọkùnrin Memfisi àti Tafanesi wọ́n ti fa adé orí rẹ yọ.
17 Ɛnyɛ wo na woama eyi aba wo so sɛ wopaa Awurade wo Nyankopɔn akyi, wɔ bere a ɔrekyerɛ wo kwan no?
Ẹ̀yin kò ha a ti fa èyí sórí ara yín nípa kíkọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀ nígbà tí ó tọ́ ọ lójú ọ̀nà?
18 Afei adɛn nti na wokɔ Misraim kɔnom Sihor mu nsu? Na adɛn nti na wokɔ Asiria kɔnom Asubɔnten no mu nsu?
Kí ló dé tí o ṣe wá lọ Ejibiti láti lọ mu omi ní Ṣihori? Kí ló dé tí o sì fi lọ sí Asiria láti lọ mú omi ni odò Eufurate náà?
19 Wo amumɔyɛ bɛtwe wʼaso; wo nsanakyi bɛka wʼanim. Enti dwene ho na hu sɛ, sɛ wopa Awurade wo Nyankopɔn akyi na woannya ne ho suro a, ɛyɛ bɔne ne ɔyaw ma wo.” Awurade, Asafo Awurade na ose.
Iṣẹ́ búburú yín yóò fìyà jẹ yín ìpadàsẹ́yìn rẹ yóò sì bá ọ wí mọ̀ kí o sì rí i wí pé ibi àti ohun búburú yóò sì jẹ́ tìrẹ nígbà tí o ti kọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀, ẹ kò sì ní ìbẹ̀rù fún mi,” ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
20 “Tete mmere no, wububuu wo konnua mu, na wotetew wo nkɔnsɔnkɔnsɔn mu; na wokae se, ‘Merensom wo!’ Ampa, wɔ koko biara so ne dua biara a adennan ase na wotena bɔɔ aguaman.
“Nígbà àtijọ́, o ti fọ́ àjàgà rẹ sọnù, ìwọ sì já ìdè rẹ; ìwọ wí pé, ‘Èmi kì yóò sìn ọ́!’ Lóòtítọ́, lórí gbogbo òkè gíga ni àti lábẹ́ igi tí ó tànkálẹ̀ ni ìwọ dùbúlẹ̀ sí gẹ́gẹ́ bí panṣágà.
21 Miduaa wo sɛ bobe ankasa a efi bobe a ase ye pa ara mu. Na ɛyɛɛ dɛn na wodan wʼakyi kyerɛɛ me bɛyɛɛ bobe a anyin asɛe wɔ wura mu yi?
Èmi ti gbìn ọ́ gẹ́gẹ́ bí àjàrà ọ̀tọ̀, gẹ́gẹ́ bí ìṣúra ọlọ́lá. Báwo wá ni ìwọ ṣe yípadà sí mi di àjàrà búburú àti aláìmọ́?
22 Sɛ wode soda ne samina bebree guare mpo a, wʼafɔdi nkekae da so wɔ mʼanim ara,” sɛnea Otumfo Awurade se ni.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o wẹ ara rẹ pẹ̀lú sódà tí o sì lo ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọṣẹ síbẹ̀síbẹ̀ èérí ni ẹ̀ṣẹ̀ rẹ níwájú,” ni Olúwa Olódùmarè wí.
23 “Ɛbɛyɛ dɛn na woaka se, ‘Me ho nguu fi ɛ; minnii Baalnom akyi ɛ’? Hwɛ sɛnea woyɛɛ wo ho wɔ obon no mu; dwene nea woayɛ no ho. Woyɛ yomabere hoɔharefo a wutu mmirika kɔ ha ba ha,
“Báwo ni ìwọ ṣe wí pé, ‘Èmi kò ṣe aláìmọ́, Èmi kò sá à tẹ̀lé àwọn Baali’? Wo bí o ṣe hùwà ní àfonífojì; wo ohun tí o ṣe. Ìwọ jẹ́ abo ìbákasẹ tí ń sá síyìn-ín sọ́hùn-ún.
24 wura mu afurum a nweatam so tena akokwaw no, ohuahua bere a ɔpɛ sɛ onini hyia no. Sɛ nʼakɔnnɔ no ano yɛ den a hena na obesianka no? Anini biara a wɔtaa no no nhaw wɔn ho bebree; edu bere a ɛsɛ sɛ wohyia no a wobenya no.
Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó tí ń gbé aginjù tí ń fa ẹ̀fúùfù ìfẹ́ sí i mu rẹ, ta ni ó le è mú dúró ní àkókò rẹ̀? Kí gbogbo àwọn akọ ẹran tí o wá a kiri kì ó má ṣe dá ara wọn lágara, nítorí wọn yóò rí ní àkókò oṣù rẹ̀.
25 Ntu mmirika nkosi sɛ wʼanan ase bɛyɛ kwaterekwa, na wo mene mu bɛyow. Nanso wokae se, ‘So nni mfaso! Mepɛ ananafo anyame, na ɛsɛ sɛ midi wɔn akyi.’
Dá ẹsẹ̀ dúró láìwọ bàtà, àti ọ̀fun rẹ nínú òǹgbẹ. Ṣùgbọ́n ìwọ wí pé, ‘Asán ni! Èmi fẹ́ràn àwọn ọlọ́run àjèjì, àwọn ni èmi yóò tọ̀ lẹ́yìn.’
26 “Sɛnea wɔkyere ɔkorɔmfo a wogu nʼanim ase no, saa na wɔagu Israelfi anim ase, wɔn ankasa, wɔn ahemfo ne wɔn adwumayɛfo, wɔn asɔfo ne wɔn adiyifo.
“Gẹ́gẹ́ bí a ṣe ń dójútì olè nígbà tí a bá mú u, bẹ́ẹ̀ náà ni ojú yóò ti ilé Israẹli— àwọn ọba àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn àlùfáà àti wòlíì wọn pẹ̀lú.
27 Wɔka kyerɛ dua se, ‘Woyɛ mʼagya,’ ne ɔbo se, ‘Wo na wowoo me.’ Wɔadan wɔn akyi akyerɛ me na ɛnyɛ wɔn anim; nanso sɛ amanehunu bi ba wɔn so a, wɔka se, ‘Bra begye yɛn!’
Wọ́n sọ fún igi pé, ‘Ìwọ ni baba mi,’ àti sí òkúta wí pé, ‘Ìwọ ni ó bí mi,’ wọ́n ti kọ ẹ̀yìn wọn sí mi, wọn kò kọ ojú sí mi síbẹ̀ nígbà tí wọ́n bá wà nínú ìṣòro, wọn yóò wí pé, ‘Wá kí o sì gbà wá!’
28 Anyame a moyɛ maa mo ho no wɔ he? Momma wɔmmra sɛ wobetumi agye mo bere a mowɔ amanehunu mu! Efisɛ mowɔ anyame bebree te sɛ nea mowɔ nkurow bebree no, Yuda.
Níbo wá ni àwọn ọlọ́run tí ẹ ṣe fúnra yín ha a wà? Jẹ́ kí wọ́n wá kí wọ́n sì gbà yín nígbà tí ẹ bá wà nínú ìṣòro! Nítorí pé ẹ̀yin ní àwọn ọlọ́run púpọ̀, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ni àwọn ìlú, ìwọ Juda.
29 “Adɛn nti na mobɔ me sobo? Mo nyinaa ayɛ dɔm atia me,” Awurade na ose.
“Kí ló dé tí o ṣe wá ń fi ẹ̀sùn kàn mí? Gbogbo yín ni ó ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi,” ni Olúwa wí.
30 “Metwee mo nkurɔfo aso kwa; wɔamfa me nteɛso. Wʼafoa akunkum wʼadiyifo te sɛ gyata a nʼani abere.
“Nínú asán mo fìyà jẹ àwọn ènìyàn yín, wọn kò sì gba ìbáwí. Idà yín ti pa àwọn wòlíì yín run, gẹ́gẹ́ bí kìnnìún tí ń bú ramúramù.
31 “Mo nnɛmmafo, munnwen Awurade asɛm ho: “Mayɛ sɛ, nweatam ama Israel ana? Anaasɛ asase a so aduru sum kabii ana? Adɛn nti na me nkurɔfo ka se, ‘Yɛwɔ ho kwan sɛ yekyinkyin; yɛremma wo nkyɛn bio.’
“Ẹ̀yin ìran yìí, ẹ kíyèsi ọ̀rọ̀ Olúwa: “Mo ha ti di aginjù sí Israẹli tàbí mo jẹ ilẹ̀ olókùnkùn biribiri? Èéṣe tí àwọn ènìyàn mi ṣe wí pé, ‘A ní àǹfààní láti máa rìn kiri; àwa kì yóò tọ̀ ọ́ wá mọ́?’
32 Ɔbabun werɛ fi ne mpempranne, ayeforo werɛ befi nʼahyehyɛde ana? Nanso me nkurɔfo werɛ afi me nna a wontumi nkan.
Wúńdíá ha le gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀, tàbí ìyàwó ohun ọ̀ṣọ́ ìgbéyàwó rẹ̀? Síbẹ̀, àwọn ènìyàn mi ti gbàgbé mi ní ọjọ́ àìníye.
33 Hwɛ nyansa a mowɔ de pɛ mo adɔfo! Mmea a wɔnsɛ hwee koraa tumi sua mo akwan.
Ìwọ ti jẹ́ ọlọ́gbọ́n tó nípa ọ̀rọ̀ ìfẹ́! Àwọn obìnrin búburú yóò kẹ́kọ̀ọ́ nípa ọ̀nà rẹ.
34 Mo adurade mu wɔ ahiafo a wodi bem mogya, nanso moankyere wɔn sɛ wɔrebubu akɔ mu. Eyinom nyinaa akyi
Lórí aṣọ rẹ ni wọ́n bá ẹ̀jẹ̀ àwọn tálákà aláìṣẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kò ká wọn mọ́ níbi tí wọ́n ti ń rùn wọlé. Síbẹ̀ nínú gbogbo èyí
35 woka se, ‘Midi bem; ne bo mfuw me.’ Nanso mebu wo atɛn efisɛ woka se, ‘Menyɛɛ bɔne biara ɛ.’
ìwọ sọ wí pé, ‘Èmi jẹ́ aláìṣẹ̀; kò sì bínú sí mi.’ Èmi yóò mú ìdájọ́ mi wá sórí rẹ nítorí pé ìwọ wí pé, ‘Èmi kò dẹ́ṣẹ̀.’
36 Adɛn nti na wukyinkyin sɛɛ, sesa wʼakwan? Misraim bedi wo huammɔ sɛnea Asiria yɛe no.
Èéṣe tí ìwọ fi ń lọ káàkiri láti yí ọ̀nà rẹ padà? Ejibiti yóò dójútì ọ́ gẹ́gẹ́ bí i ti Asiria.
37 Afei wubefi saa beae hɔ a wo nsa gu wo ti so. Efisɛ Awurade apo wɔn a wode wo ho too wɔn so no; wɔremmoa wo.
Ìwọ yóò sì fi ibẹ̀ sílẹ̀ pẹ̀lú kíkáwọ́ rẹ lé orí rẹ, nítorí pé Olúwa ti kọ̀ àwọn tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé sílẹ̀, kì yóò sí ìrànlọ́wọ́ kankan fún ọ láti ọ̀dọ̀ wọn.

< Yeremia 2 >