< Yesaia 63 >

1 Hena ne oyi a ofi Edom reba, nea ofi Bosra a nkekae kɔkɔɔ wɔ nʼatade mu yi? Hena ne oyi a wɔahyehyɛ no kɔsɔɔ yi, a ɔde nʼahoɔden kɛse retutu taataa yi? “Ɛyɛ me a, mekasa wɔ trenee mu, nea otumi gye nkwa no.”
Ta nì eléyìí tí ó Edomu wá, ti òun ti aṣọ àrẹpọ́n láti Bosra wá? Ta nì eléyìí, tí ó ní ògo nínú aṣọ rẹ̀, tí ó ń yan bọ̀ wá nínú ọláńlá agbára rẹ̀? “Èmi ni ẹni tí ó ń sọ̀rọ̀ nínú òdodo tí ó ní ipa láti gbàlà.”
2 Adɛn nti na mo ntade bere kɔɔ, te sɛ obi a ɔretiatia nsakyiamoa so de yi?
Èéṣe tí aṣọ yín fi pupa gẹ́gẹ́ bí i tàwọn tí ń ṣiṣẹ́ ní ìfúntí?
3 “Me nko ara atiatia nsakyiamoa so, na amanaman no mu obiara anka me ho. Mitiatia wɔn so wɔ mʼabufuw mu na mimiaa wɔn so wɔ mʼabufuwhyew mu; wɔn mogya bɔ petee me ntade mu, maa nkekae yɛɛ mʼadurade nyinaa mu.
“Èmi nìkan ti dá tẹ ìfúntí wáìnì; láti àwọn orílẹ̀-èdè tí ẹnikẹ́ni kò sì wà pẹ̀lú mi. Mo tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ ní ìbínú mi mo sì tẹ̀ wọ́n rẹ́ ní ìrunú mi ẹ̀jẹ̀ wọn sì fọ́n sí aṣọ mi, mo sì da àbàwọ́n sí gbogbo aṣọ mi.
4 Na aweretɔda wɔ me koma mu na me gye afe aba.
Nítorí ọjọ́ ẹ̀san wà ní ọkàn mi àti pé ọdún ìràpadà mi ti dé.
5 Mehwɛe, nanso na ɔboafo biara nni hɔ, ɛyɛɛ me ahodwiriw sɛ obiara anso me mu; enti mʼankasa abasa yɛɛ nkwagyedwuma maa me, na mʼabufuw wowaw me.
Mo wò, ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan láti ṣe ìrànwọ́. Àyà fò mí pé ẹnikẹ́ni kò ṣèrànwọ́; nítorí náà apá mi ni ó ṣiṣẹ́ ìgbàlà fún mi àti ìrunú mi ni ó gbé mi ró.
6 Mitiatiaa amanaman no so wɔ mʼabufuw mu; mema wɔbobowee wɔ mʼabufuwhyew mu na mihwiee wɔn mogya guu fam.”
Mo tẹ orílẹ̀-èdè mọ́lẹ̀ nínú ìbínú mi; nínú ìrunú mi mo jẹ́ kí wọ́n mu mo sì da ẹ̀jẹ̀ wọn sílẹ̀ lórí erùpẹ̀.”
7 Mɛka Awurade ayamye ho asɛm, ne nneyɛe a enti ɔsɛ ayeyi, wɔ nea Awurade ayɛ ama yɛn nyinaa ho Yiw, wɔ nneɛma pa bebree a wayɛ ama Israelfifo. Wɔ nʼayamhyehye ne ne mmɔborɔhunu a ɛdɔɔso no nti.
Èmi yóò sọ nípa àánú Olúwa, ìṣe rẹ gbogbo tí ó yẹ kí a yìn ín fún, gẹ́gẹ́ bí ohun tí Olúwa ti ṣe fún wa, bẹ́ẹ̀ ni, ohun rere gbogbo tí ó ti ṣe fún ilé Israẹli, gẹ́gẹ́ bí àánú àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ oore rẹ̀.
8 Ɔkae se, “Ampa ara wɔyɛ me nkurɔfo, mmabarima a wɔrenni me huammɔ;” ɛno nti ɔbɛyɛɛ wɔn Agyenkwa.
Ó wí pé, “Lóòtítọ́ ènìyàn mi ni wọ́n, àwọn ọmọ tí kì yóò jẹ́ òpùrọ́ fún mi”; bẹ́ẹ̀ ni, ó sì di Olùgbàlà wọn.
9 Wɔn amanehunu nyinaa mu, ɔno nso huu amane, na ɔbɔfo a ɔka ne ho no nso gyee wɔn. Ne dɔ ne ne mmɔborɔhunu mu, ogyee wɔn; ɔmaa wɔn so na ɔsoaa wɔn mfe a atwa mu no nyinaa mu.
Nínú gbogbo ìpọ́njú wọn, inú òun pẹ̀lú bàjẹ́ àti angẹli tí ó wà níwájú rẹ̀ gbà wọ́n là. Nínú ìfẹ́ àti àánú rẹ̀, ó rà wọ́n padà; ó gbé wọn sókè ó sì pọ̀n wọ́n ní gbogbo ọjọ́ ìgbà n nì.
10 Nanso wɔtew atua de how ne Honhom Kronkron werɛ. Enti ɔbɛyɛɛ wɔn tamfo na ɔno ankasa ko tiaa wɔn.
Síbẹ̀síbẹ̀ wọ́n ṣọ̀tẹ̀ wọ́n sì ba Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ̀ nínú jẹ́. Bẹ́ẹ̀ ni ó yípadà ó sì di ọ̀tá wọn òun tìkára rẹ̀ sì bá wọn jà.
11 Afei ne nkurɔfo kae tete nna no, Mose ne ne nkurɔfo nna no. Ɛhe na nea ɔde wɔn faa po mu no wɔ? Ɔne ne nguan no hwɛfo no? Ɛhe na nea ɔmaa ne Honhom Kronkron no tenaa wɔn mu no wɔ,
Lẹ́yìn náà ni àwọn ènìyàn rẹ̀ rántí ọjọ́ ìgbà n nì, àwọn ọjọ́ Mose àti àwọn ènìyàn rẹ̀ níbo ni ẹni náà wà tí ó mú wọn la Òkun já, pẹ̀lú olùṣọ́-àgùntàn agbo ẹran rẹ̀? Níbo ni ẹni náà wà tí ó rán Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ̀ sáàrín wọn,
12 nea ɔsomaa nʼanuonyam basa a ɛwɔ tumi sɛ ommegyina Mose nsa nifa so no, nea ɔpaee asu no mu wɔ wɔn anim, de gyee din maa ne ho afebɔɔ no,
ta ni ó rán apá ògo ti agbára rẹ̀ láti wà ní apá ọ̀tún Mose, ta ni ó pín omi ní yà níwájú wọn, láti gba òkìkí ayérayé fún ara rẹ̀,
13 nea odii wɔn anim faa bun mu sɛnea ɔpɔnkɔ fa asase tamaa so, wɔanhintiw;
ta ni ó síwájú wọn la àwọn ọ̀gbun nì já? Gẹ́gẹ́ bí ẹṣin ni gbangba ìlú wọn tí kò sì kọsẹ̀;
14 te sɛ anantwi a wɔkɔ sare so, Awurade Honhom ma wɔhomee. Sɛnea wokyerɛɛ wo nkurɔfo kwan de gyee anuonyam abodin maa wo ho ni.
gẹ́gẹ́ bí ọ̀wọ́ ẹran tí ó lọ sí pápá oko, a fún wọn ní ìsinmi láti ọwọ́ Ẹ̀mí Olúwa. Báyìí ni ẹ ṣe tọ́ àwọn ènìyàn yín láti fún ara yín ní orúkọ kan tí ó lógo.
15 Brɛ wʼani ase hwɛ fam fi wʼahengua a ɛkorɔn, ɛyɛ kronkron na ho wɔ nyam no so. Mo mmɔdemmɔ ne mo ahoɔden wɔ he? Wɔayi wʼayamhyehye ne wʼahummɔbɔ afi yɛn so.
Bojú wolẹ̀ láti ọ̀run kí o sì rí i láti ìtẹ́ ògo rẹ, mímọ́ àti ológo. Níbo ni ìtara àti agbára rẹ wà? Ìwà jẹ́ẹ́jẹ́ rẹ àti àánú rẹ ni a ti mú kúrò níwájú wa.
16 Nanso wo ara wo ne yɛn Agya ɛwɔ mu, Abraham nnim yɛn na Israel nso nnye yɛn nto mu de; nanso wo, Awurade, wo ne yɛn Agya; efi tete, wo din ne; Yɛn Gyefo.
Ṣùgbọ́n ìwọ ni baba wa, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Abrahamu kò mọ̀ wá tàbí Israẹli mọ ẹni tí à á ṣe; ìwọ, Olúwa ni Baba wa, Olùràpadà wa láti ìgbà n nì ni orúkọ rẹ.
17 Adɛn, Awurade, na woma yɛkwati wʼakwan na wupirim yɛn koma enti ɛmma yenni wo ni? San bra, esiane wʼasomfo, mmusuakuw a wɔyɛ wʼagyapade no nti.
Èéṣe Olúwa tí o fi jẹ́ kí a ṣáko kúrò ní ojú ọ̀nà rẹ tí o sì ṣé àyà wa le tó bẹ́ẹ̀ tí àwa kò fi bọ̀wọ̀ fún ọ? Padà nítorí àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ẹ̀yà tí ṣe ogún ìní rẹ.
18 Bere tiaa bi mu wo nkurɔfo faa wo kronkronbea nanso mprempren yɛn atamfo atiatia so.
Fún ìgbà díẹ̀ ni àwọn ènìyàn rẹ fi gba ibi mímọ́ rẹ, ṣùgbọ́n nísinsin yìí àwọn ọ̀tá wa ti tẹ ibi mímọ́ rẹ mọ́lẹ̀.
19 Enti yɛyɛ wo de fi tete, nanso wɔn de, wunnii wɔn so hene na wɔmmɔɔ wo din mfrɛɛ wɔn da.
Àwa jẹ́ tìrẹ láti ìgbà n nì; ṣùgbọ́n ìwọ kò tí ì jẹ ọba lé wọn lórí, a kò sì tí ì pè wọ́n mọ́ orúkọ rẹ.

< Yesaia 63 >