< Hosea 14 >

1 Israel, san wʼakyi kɔ Awurade wo Nyankopɔn nkyɛn. Wʼasehwe fi wo bɔne!
Yípadà ìwọ Israẹli sí Olúwa Ọlọ́run rẹ. Ẹ̀ṣẹ̀ rẹ ló fa ìparun rẹ!
2 Fa wo nsɛm a wowɔ san kɔ Awurade nkyɛn. Ka kyerɛ no se, “Fa yɛn bɔne nyinaa kyɛ yɛn, na fa ahummɔbɔ gye yɛn, na yɛatumi ayi wo ayɛ.
Ẹ gba ọ̀rọ̀ Olúwa gbọ́, kí ẹ sì yípadà sí Olúwa. Ẹ sọ fún un pé, “Darí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá kí o sì fi oore-ọ̀fẹ́ gbà wá, kí àwa kí ó lè fi ètè wa sán an fún ọ
3 Asiria rentumi nnye yɛn; yɛrentena akofo apɔnkɔ so. Yɛrenka bio da se, ‘Yɛn anyame’ nkyerɛ nea yɛn ara de yɛn nsa ayɛ, na wo mu na ayisaa nya mmɔborɔhunu.”
Asiria kò le gbà wá là; a kò ní í gorí ẹṣin ogun. A kò sì ní tún sọ ọ́ mọ́ láé, ‘Àwọn ni òrìṣà wa’ sí àwọn ohun tí ó fi ọwọ́ wa ṣe; nítorí pé lọ́dọ̀ rẹ ni àwọn aláìní baba tí ń rí àánú.”
4 “Mɛsa wɔn asoɔden yare. Mefi me koma mu adɔ wɔn, efisɛ mʼabufuw nni wɔn so bio.
“Èmi wo àgàbàgebè wọn sàn, Èmi ó sì fẹ́ràn wọn, lọ́fẹ̀ẹ́, nítorí ìbínú mi ti yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn.
5 Mɛyɛ sɛ obosu ama Israel. Ɔbɛfefɛw ayɛ frɔmfrɔm te sɛ sukooko. Te sɛ Lebanon sida no, ɔde ne ntin betim fam;
Èmi o dàbí ìrì sí Israẹli, wọn o sì yọ ìtànná bi ewéko lílì. Bi kedari ti Lebanoni yóò si ta gbòǹgbò.
6 ne mman bɛdennan. Nʼahoɔfɛ bɛyɛ sɛ ngodua, na ne hua ayɛ sɛ Lebanon sida.
Àṣẹ̀ṣẹ̀yọ ẹ̀ka rẹ̀ yóò dàgbà, dídán ẹwà yóò rẹ̀ dànù bí igi olifi. Òórùn rẹ yóò sì dàbí igi kedari ti Lebanoni.
7 Nnipa bɛtena ne nwini ase bio. Obenyin ayɛ frɔmfrɔm te sɛ aburow. Ɔbɛfefɛw ayɛ frɔmfrɔm te sɛ bobe, na ne din a ahyeta bɛyɛ sɛ nsa a efi Lebanon.
Àwọn ènìyàn yóò tún padà gbé lábẹ́ òjijì rẹ̀. Yóò rúwé bi ọkà. Yóò sì yọ ìtànná bi àjàrà, òórùn rẹ yóò dàbí ti wáìnì Lebanoni.
8 Efraim dɛn na me ne ahoni wɔ yɛ bio? Megye no so na mʼani aku ne ho. Mete sɛ dua a nʼahaban mpo; sɛ wobɛsow aba a, egyina me so.”
Ìwọ Efraimu, kín ló tún kù tí mo ní ṣe pẹ̀lú ère òrìṣà? Èmi ó dá a lóhùn, èmi ó sì ṣe ìtọ́jú rẹ. Mo dàbí igi junifa tó ń fi gbogbo ìgbà tutù, èso tí ìwọ ń so si ń wá láti ọ̀dọ̀ mi.”
9 Hena ne onyansafo? Obehu eyinom mu. Hena na ɔwɔ nhumu? Ɔbɛte eyinom ase. Awurade akwan teɛ. Atreneefo nantew so, nanso asoɔdenfo hintiw wɔ mu.
Ta ni ọlọ́gbọ́n? Òun yóò mòye àwọn nǹkan wọ̀nyí. Ta a ní ó mọ̀? Òun yóò ní ìmọ̀ wọn. Títọ́ ni ọ̀nà Olúwa àwọn olódodo si ń rìn nínú wọn, ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́tẹ̀ ni yóò kọsẹ̀ nínú wọn.

< Hosea 14 >