< Mezmurlar 27 >

1 Davut'un mezmuru RAB benim ışığım, kurtuluşumdur, Kimseden korkmam. RAB yaşamımın kalesidir, Kimseden yılmam.
Ti Dafidi. Olúwa ni ìmọ́lẹ̀ mi àti ìgbàlà mi; ta ni èmi yóò bẹ̀rù? Olúwa ni ibi ìsádi ẹ̀mí mi, ẹ̀rù ta ni yóò bà mí?
2 Hasımlarım, düşmanlarım olan kötüler, Beni yutmak için üzerime gelirken Tökezleyip düşerler.
Nígbà tí àwọn ènìyàn búburú kọjú ìjà sí mi láti jẹ ẹran-ara mi, àní àwọn ọ̀tá mi àti àwọn abínúkú mi, wọn yóò kọsẹ̀, wọn yóò sì ṣubú.
3 Karşımda bir ordu konaklasa, Kılım kıpırdamaz, Bana karşı savaş açılsa, Yine güvenimi yitirmem.
Bí ọmọ-ogun tilẹ̀ yí mi ká tí wọ́n sì dìde sí mi, ọkàn mi kì yóò bẹ̀rù; bí ogun tilẹ̀ dìde sí mi, nínú èyí ni ọkàn mi yóò le.
4 RAB'den tek dileğim, tek isteğim şu: RAB'bin güzelliğini seyretmek, Tapınağında O'na hayran olmak için Ömrümün bütün günlerini O'nun evinde geçirmek.
Ohun kan ni mo béèrè lọ́dọ̀ Olúwa, òhun ni èmi yóò máa wá kiri: kí èmi kí ó le wà ní ilé Olúwa ní ọjọ́ ayé mi gbogbo, kí èmi: kí ó le kíyèsi ẹwà Olúwa, kí èmi kí ó sì máa wà ní tẹmpili rẹ̀.
5 Çünkü O kötü günde beni çardağında gizleyecek, Çadırının emin yerinde saklayacak, Yüksek bir kaya üzerine çıkaracak beni.
Nítorí pé ní ìgbà ìpọ́njú òun yóò pa mí mọ́ nínú àgọ́ rẹ̀; níbi ìkọ̀kọ̀ àgọ́ rẹ̀ ni òun yóò pa mí mọ́; yóò sì gbé mi sókè lórí àpáta.
6 O zaman çevremi saran düşmanlarıma karşı Başım yukarı kalkacak, Sevinçle haykırarak kurbanlar sunacağım O'nun çadırında, O'nu ezgilerle, ilahilerle öveceğim.
Ní ìsinsin yìí, a ti gbé orí mi sókè ga ju ti àwọn ọ̀tá mi lọ tí ó yí mí ká; èmi yóò rú ẹbọ nínú àgọ́ rẹ, ẹbọ ariwo àti ti ayọ̀; èmi yóò kọrin àní orin dídùn sí Olúwa.
7 Sana yakarıyorum, ya RAB, kulak ver sesime, Lütfet, yanıtla beni!
Gbọ́ ohùn mi nígbà tí ẹ̀mí bá à ń pè, Olúwa, ṣe àánú fún mi kí o sì dá mi lóhùn,
8 Ya RAB, içimden bir ses duydum: “Yüzümü ara!” dedin, İşte yüzünü arıyorum.
Ọkàn mi wí pé, “Wá ojú u rẹ̀!” Ojú rẹ, Olúwa, ni ti èmí ń wá.
9 Yüzünü benden gizleme, Kulunu öfkeyle geri çevirme! Bana hep yardımcı oldun; Bırakma, terk etme beni, Ey beni kurtaran Tanrı!
Má ṣe fi ojú rẹ pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ mi, má ṣe fi ìbínú sá ìránṣẹ́ rẹ tì; ìwọ tí o ti jẹ́ olùrànlọ́wọ́ mi, Má ṣe fi mí sílẹ̀, má sì ṣe kọ̀ mí, háà! Ọlọ́run ìgbàlà mi.
10 Annemle babam beni terk etseler bile, RAB beni kabul eder.
Bí ìyá àti baba bá kọ̀ mí sílẹ̀, Olúwa yóò tẹ́wọ́ gbà mí.
11 Ya RAB, yolunu öğret bana, Düşmanlarıma karşı Düz yolda bana öncülük et.
Kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, Olúwa, kí o sì sìn mi lọ sí ọ̀nà tí ó tẹ́jú nítorí àwọn ọ̀tá mi.
12 Beni hasımlarımın keyfine bırakma, Çünkü yalancı tanıklar dikiliyor karşıma, Ağızları şiddet saçıyor.
Má ṣe fi mí lé ìfẹ́ àwọn ọ̀tá mi lọ́wọ́, nítorí àwọn ẹlẹ́rìí èké ti dìde sí mi, wọ́n sì mí ìmí ìkà.
13 Yaşam diyarında RAB'bin iyiliğini göreceğimden kuşkum yok.
Èmi ní ìgbàgbọ́ pé, èmi yóò rí ìre Olúwa ní ilẹ̀ alààyè.
14 Umudunu RAB'be bağla, Güçlü ve yürekli ol; Umudunu RAB'be bağla!
Dúró de Olúwa; kí ó jẹ alágbára, kí o sì mú ọkàn le àní dúró de Olúwa.

< Mezmurlar 27 >