< Çölde Sayim 15 >

1 RAB Musa'ya şöyle dedi:
Olúwa sọ fún Mose pé,
2 “İsrail halkına de ki, ‘Yerleşmek için size vereceğim ülkeye girince,
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí èmi ó fún yin gẹ́gẹ́ bí ibùgbé
3 RAB'bi hoşnut eden bir koku yapmak için yakmalık sunu, özel adak kurbanı, gönülden verilen sunu ya da bayram sunusu gibi yakılan sunu olarak RAB'be sığır ya da davar sunacaksınız.
tí ẹ̀yin ó bá sì ṣe ẹbọ iná sí Olúwa ẹbọ sísun, tàbí ẹbọ, láti san ẹ̀jẹ́ pàtàkì tàbí ọrẹ àtinúwá, tàbí nínú àjọ yín, láti ṣe òórùn dídùn sí Olúwa nínú agbo ẹran tàbí ọ̀wọ́ ẹran,
4 Sunu sunan kişi RAB'be tahıl sunusu olarak dörtte bir hin zeytinyağıyla yoğrulmuş onda bir efa ince un sunacak.
nígbà náà ni kí ẹni tí ó bá mú ọrẹ rẹ̀ wá, yóò tún mú ẹbọ ohun jíjẹ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná pẹ̀lú ìdámẹ́rin òsùwọ̀n òróró wá síwájú Olúwa.
5 Yakmalık sunu ya da kurban için, her kuzuya dökmelik sunu olarak dörtte bir hin şarap hazırla.
Pẹ̀lú ọ̀dọ́-àgùntàn kọ̀ọ̀kan yálà fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun ni, kí ẹ pèsè ìdámẹ́rin òsùwọ̀n wáìnì gẹ́gẹ́ bí ohun mímu.
6 “‘Koç sunarken tahıl sunusu olarak üçte bir hin zeytinyağıyla yoğrulmuş onda iki efa ince un hazırla.
“‘Fún àgbò kan ni kí ẹ pèsè ọrẹ ohun jíjẹ ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n òróró pò.
7 Dökmelik sunu olarak da üçte bir hin şarap sun. Bunları RAB'bi hoşnut eden koku olarak sunacaksın.
Àti ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n wáìnì fún ọrẹ ohun mímu gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn sí Olúwa.
8 RAB'be yakmalık sunu, özel adak kurbanı ya da esenlik sunusu olarak bir boğa sunduğunda,
“‘Nígbà tí ẹ bá sì pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun, láti fi san ẹ̀jẹ́ tàbí fún ọrẹ àlàáfíà sí Olúwa,
9 boğayla birlikte tahıl sunusu olarak yarım hin zeytinyağıyla yoğrulmuş onda üç efa ince un sun.
ẹni náà yóò mú ọ̀dọ́ akọ màlúù náà wá pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ, ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdajì òsùwọ̀n òróró pò.
10 Ayrıca dökmelik sunu olarak yarım hin şarap sun. Yakılan bu sunu RAB'bi hoşnut eden bir koku olacak.
Kí ó tún mú ìdajì òsùwọ̀n wáìnì wá fún ọrẹ ohun mímu. Yóò jẹ́ ọrẹ àfinásun, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
11 Sığır, koç, davar –kuzu ya da keçi– böyle hazırlanacak.
Báyìí ni kí ẹ ṣe pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù tàbí àgbò, ọ̀dọ́-àgùntàn tàbí ọmọ ewúrẹ́.
12 Kaç hayvan sunacaksan her biri için aynı şeyleri yapacaksın.
Ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ fún ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn, iyekíye tí ẹ̀yin ìbá à pèsè.
13 “‘Her İsrail yerlisi RAB'bi hoşnut eden koku olarak yakılan bir sunu sunarken bunları aynen yapmalıdır.
“‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín ni kí ó máa ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí nígbà tí ó bá mú ọrẹ àfinásun gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn wá fún Olúwa.
14 Kuşaklar boyunca aranızda yaşayan bir yabancı ya da yerli olmayan bir konuk, RAB'bi hoşnut eden koku olarak yakılan bir sunu sunarken, sizin uyguladığınız kuralları uygulamalıdır.
Bí àlejò kan bá ń gbé láàrín yín ní gbogbo ìran yín, bí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá fẹ́ mú ọrẹ àfinásun bí òórùn dídùn wá fún Olúwa, gbogbo bí ẹ bá ṣe ń ṣe náà ni kí ó ṣe.
15 Sizin ve aranızda yaşayan yabancılar için topluluk aynı kuralları uygulamalıdır. Kuşaklar boyunca kalıcı bir kural olacak bu. RAB'bin önünde siz nasılsanız, aranızda yaşayan yabancı da aynı olacak.
Gbogbo ìjọ ènìyàn gbọdọ̀ ní òfin kan náà fún ọmọ bíbí ilẹ̀ yín àti fún àwọn àlejò tó ń gbé láàrín yín, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún àwọn ìran tó ń bọ̀. Ẹ̀yin àti àlejò tó ń gbé láàrín yín sì jẹ́ bákan náà níwájú Olúwa.
16 Size de aranızda yaşayan yabancıya da aynı yasalar ve kurallar uygulanacak.’”
Òfin kan àti ìlànà kan ni yóò wà fún yín àti fún àwọn àlejò tí ń gbé láàrín yín.’”
17 RAB Musa'ya şöyle dedi:
Olúwa sọ fún Mose pé,
18 “İsrail halkına de ki, ‘Sizi götüreceğim ülkeye girip
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mo ń mú yín lọ.
19 o ülkenin ekmeğinden yediğinizde, bir kısmını bana sunacaksınız.
Tí ẹ sì jẹ oúnjẹ ilẹ̀ náà, ẹ mú nínú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè wá fún Olúwa.
20 İlk tahılınızdan sunu olarak bir pide sunacaksınız; bunu harmanınızdan bir sunu olarak sunacaksınız.
Ẹ mú àkàrà wá nínú àkọ́so oúnjẹ yín wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè sí Olúwa, ọrẹ láti inú ilẹ̀ ìpakà yín.
21 İlk tahılınızdan yapılmış bu sunuyu kuşaklar boyunca RAB'be sunacaksınız.’”
Nínú àkọ́so oúnjẹ yín ni kí ẹ ti máa mú ọrẹ ìgbésókè yìí fún Olúwa.
22 “‘Eğer bilmeden günah işlediyseniz, RAB'bin Musa'ya verdiği buyruklardan herhangi birini –RAB'bin buyruk verdiği günden başlayarak Musa aracılığıyla size ve gelecek kuşaklara buyurduğu herhangi bir şeyi– yerine getirmediyseniz
“‘Bí ẹ bá kùnà láìròtẹ́lẹ̀ láti pa àwọn òfin tí Olúwa fún Mose mọ́,
èyí ni gbogbo òfin tí Olúwa fún yín láti ẹnu Mose láti ọjọ́ tí Olúwa ti fún yín àti títí dé ìran tó ń bọ̀.
24 ve bu günah bilmeden işlendiyse, bütün topluluk RAB'bi hoşnut eden koku sunmak için yakmalık sunu olarak istenilen tahıl ve dökmelik sunuyla birlikte bir boğa, günah sunusu olarak da bir teke sunacaktır.
Bí ẹ̀ṣẹ̀ bá wáyé láìròtẹ́lẹ̀ láìjẹ́ pé ìjọ ènìyàn mọ̀ sí i, nígbà náà ni kí gbogbo ìjọ ènìyàn mú ọ̀dọ́ akọ màlúù kan wá fún ẹbọ sísun bí òórùn dídùn sí Olúwa, pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà, pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
25 Kâhin bütün İsrail topluluğunun günahını bağışlatacak, halk bağışlanacak. Çünkü bilmeyerek günah işlediler. İşledikleri günah yüzünden RAB için yakılan sunu olarak sunularını ve günah sunularını sundular.
Àlùfáà yóò sì ṣe ètùtù, fun gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, a ó sì dáríjì wọ́n, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀, wọ́n sì ti mú ọrẹ àfinásun wá fún Olúwa nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n ṣẹ̀.
26 Bütün İsrail topluluğu da aranızda yaşayan yabancılar da bağışlanacaktır. Çünkü halk bilmeyerek bu günahı işledi.
A ó dárí jí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli àti àwọn àjèjì tí ń gbé ní àárín wọn nítorí pé ní àìròtẹ́lẹ̀ ni wọ́n sẹ ẹ̀ṣẹ̀ náà.
27 “‘Eğer biri bilmeden günah işlerse, günah sunusu olarak bir yaşında bir dişi keçi getirmeli.
“‘Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé ẹnìkan ló sẹ̀ ní àìròtẹ́lẹ̀, kí ó mú abo ewúrẹ́ ọlọ́dún kan wá fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
28 Kâhin RAB'bin önünde, bilmeden günah işleyen kişinin günahını bağışlatacak. Bağışlatma yapılınca kişi bağışlanacak.
Àlùfáà yóò ṣe ètùtù níwájú Olúwa fún ẹni tó ṣẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀, tí wọ́n bá ṣe ètùtù fún un, a ó sì dáríjì í.
29 Bilmeden günah işleyen İsrail yerlisi için de aranızda yaşayan yabancı için de aynı yasayı uygulayacaksınız.
Òfin kan kí ẹ̀yin kí ó ní fún ẹnikẹ́ni tó bá ṣẹ̀ ní àìmọ̀, àti fún àwọn ẹni tí a bí nínú àwọn ọmọ Israẹli, àti fún àlejò tí ń ṣe àtìpó.
30 “‘Yerli ya da yabancı biri bilerek günah işlerse, RAB'be saygısızlık etmiştir. Bu kişi halkının arasından atılmalı.
“‘Ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni bá mọ̀ ọ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ yálà ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín tàbí àlejò, irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti kó ẹ̀gàn bá orúkọ Olúwa, a ó sì gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀.
31 RAB'bin sözünü küçümsemiş, buyruklarına karşı gelmiştir. Bu nedenle o kişi halkının arasından kesinlikle atılacak, suçunun cezasını çekecektir.’”
Nítorí pé ẹni náà ti kẹ́gàn ọ̀rọ̀ Olúwa ó sì ti rú òfin rẹ̀, a gbọdọ̀ gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀; ẹ̀bi rẹ̀ yóò sì wà lórí rẹ̀.’”
32 İsrailliler çöldeyken, Şabat Günü odun toplayan birini buldular.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli wà nínú aginjù, wọ́n rí ọkùnrin kan tí ń ṣá igi ní ọjọ́ Ìsinmi.
33 Odun toplarken adamı bulanlar onu Musa'yla Harun'un ve bütün topluluğun önüne getirdiler.
Àwọn tó sì rí i níbi tó ti ń ṣá igi wọ́n sì mú un wá sí ọ̀dọ̀ Mose àti Aaroni àti síwájú gbogbo ìjọ ènìyàn,
34 Adama ne yapılacağı belirlenmediğinden onu gözaltında tuttular.
wọ́n fi sí ìpamọ́ nítorí pé ohun tí wọn ó ṣe fún un kò tí ì yé wọn.
35 Derken RAB Musa'ya, “O adam öldürülmeli. Bütün topluluk ordugahın dışında onu taşa tutsun” dedi.
Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Kíkú ni ọkùnrin náà yóò kú kí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sọ ọ́ lókùúta pa ní ẹ̀yìn ibùdó.”
36 Böylece topluluk adamı ordugahın dışına çıkardı. RAB'bin Musa'ya buyurduğu gibi, onu taşlayarak öldürdüler.
Wọ́n mú un jáde sí ẹ̀yìn ibùdó, gbogbo ìjọ ènìyàn sì sọ ọ́ lókùúta pa, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
37 RAB Musa'ya şöyle dedi:
Olúwa sọ fún Mose pé,
38 “İsrail halkına de ki, ‘Kuşaklar boyunca giysinizin dört yanına püskül dikeceksiniz. Her püskülün üzerine lacivert bir kordon koyacaksınız.
“Bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, kí o sọ fún wọn pé: ‘Títí dé àwọn ìran tó ń bọ̀ ni kí wọn máa ṣe wajawaja sí etí aṣọ wọn, kí wọn sì fi okùn tẹ́ẹ́rẹ́ aláwọ̀ búlúù sí wajawaja kọ̀ọ̀kan.
39 Öyle ki, püskülleri gördükçe RAB'bin buyruklarını anımsayasınız. Böylelikle RAB'bin buyruklarına uyacak, yüreğinizin, gözünüzün istekleri ardınca gitmeyecek, hainlik etmeyeceksiniz.
Wajawaja yìí ni ẹ sì máa wọ̀ láti lè mú yín rántí gbogbo òfin Olúwa, kí ẹ bá à lè ṣe wọ́n, kí ẹ sì má bá à ṣe àgbèrè nípa títẹ̀lé ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn àti ojú yín.
40 Ta ki, bütün buyruklarımı anımsayıp tutasınız ve Tanrınız için kutsal olasınız.
Nígbà náà ni ẹ ó gbọ́rọ̀ láti pa gbogbo òfin mi mọ́, ẹ ó sì jẹ́ mímọ́ sí Ọlọ́run yín.
41 Tanrınız olmak için sizi Mısır'dan çıkaran Tanrınız RAB benim. Tanrınız RAB benim.’”
Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín tí ó mú yín jáde láti Ejibiti láti jẹ́ Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’”

< Çölde Sayim 15 >