< Yunus 2 >

1 Yunusee baluğne vuxhnenang'a cune Rəbbis Allahıs inəxübna düə haa'a:
Nígbà náà ni Jona gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ láti inú ẹja náà wá,
2 Rəbb, zı dağamiyvalenang'a Valqa onu'u, Ğunad alidghıniy quvuyn. Zı ahaleençe ts'ir hav'u, Vak'le yizda ts'ir g'avxhuna. (Sheol h7585)
Ó sì wí pé: “Nínú ìpọ́njú mi ni mo kígbe sí Olúwa, òun sì gbọ́ ohùn mi. Mo kígbe láti inú ipò òkú, mo pè fún ìrànwọ́, ìwọ sì gbọ́ ohùn mi. (Sheol h7585)
3 Ğu zı deryahne k'oralybışeeqa g'uvorxhul, Zı xhyanbışde yı'q'nee axu, Yiğın gırgın xhyanbıyiy dalğabı Zal ooğançe ılğeeç'u.
Nítorí tí ìwọ ti sọ mí sínú ibú, ní àárín Òkun, ìṣàn omi sì yí mi káàkiri; gbogbo bíbì omi àti rírú omi rékọjá lórí mi.
4 Manke zı uvhuyn: «Ğu zı Vake əq'əna qı'ı, Meed zak'le Yiğın muq'addasın xav İyerusalimee g'acesıncad».
Nígbà náà ni mo wí pé, ‘A ta mí nù kúrò níwájú rẹ; ṣùgbọ́n síbẹ̀ èmi yóò tún máa wo ìhà tẹmpili mímọ́ rẹ.’
5 Nafas əlyhəəsme xhyanbı zalqa qadı, K'oralybışeeqa qıkkı, Vuk'lelqad xavsiy alitk'ır.
Omi yí mi káàkiri, àní títí dé ọkàn; ibú yí mi káàkiri, a fi koríko odò wé mi lórí.
6 Suvabışde avqamee zı giç'una, İttehesu Ğu dunyeyn akkabı zal oğa it'umetxha. Ğumee yizda Rəbb Allah Yizın tan k'oralybışeençe g'attixhan hı'iyn.
Èmi sọ̀kalẹ̀ lọ sí ìsàlẹ̀ àwọn òkè ńlá; ilẹ̀ ayé pẹ̀lú ìdènà rẹ̀ yí mi ká títí: ṣùgbọ́n ìwọ ti mú ẹ̀mí mi wá sókè láti inú ibú wá, Olúwa Ọlọ́run mi.
7 Yizda ı'mı'r k'yabat'amee, Zı Rəbb yik'el qali'ı, Yizda düə Valqa, Yiğne muq'addas xaalqa hipxhırna.
“Nígbà tí ó rẹ ọkàn mi nínú mi, èmi rántí rẹ, Olúwa, àdúrà mi sì wá sí ọ̀dọ̀ rẹ, nínú tẹmpili mímọ́ rẹ.
8 Şavaayiy nişiscad karaı'dəəne bütbışis ı'bəədat ha'a, Manbışe Ğu yik'el hixan ha'a, Colqana rəhı'm avaak'an haa'a.
“Àwọn tí ń fàmọ́ òrìṣà èké kọ àánú ara wọn sílẹ̀.
9 Zımee şukur haa'ane mə'niybışika Vas q'urbanbı allya'as. Zı huvuyn cuvab cigeeqa qalya'asın. G'attivxhan haa'ana sa Rəbb Vuc vorna!
Ṣùgbọ́n èmi yóò fi orin ọpẹ́, rú ẹbọ sí ọ. Èmi yóò san ẹ̀jẹ́ tí mo ti jẹ́. ‘Ìgbàlà wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa.’”
10 Rəbbee baluğuk'le uvhuyng'a, mançin Yunus ghalençe xhyan deşde cigeeqa qığayhe.
Olúwa sì pàṣẹ fún ẹja náà, ó sì pọ Jona sí orí ilẹ̀ gbígbẹ.

< Yunus 2 >