< Luk 19 >

1 Jisu Jeriko nga vngpitla vngto.
Jesu sì wọ Jeriko lọ, ó sì ń kọjá láàrín rẹ̀.
2 Ho hoka lampu naayanv mvnwng lokv kaiyachok nvgo dooto vkvgv aminv Jakias, nw achialvbv nyitvto.
Sì kíyèsi i, ọkùnrin kan wà tí a ń pè ní Sakeu, ó sì jẹ́ olórí agbowó òde kan, ó sì jẹ́ ọlọ́rọ̀.
3 Nw Jisu yvvdw kaadubv vla rikwto, vbvritola nw adwngnv nyi gubv rito okv nyipam v twngtvnam lvkwnglo nw Jisunyi kaapa nyumato.
Ó sì ń fẹ́ láti rí ẹni tí Jesu jẹ́: kò sì lè rí i, nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn, àti nítorí tí òun jẹ́ ènìyàn kúkúrú.
4 Vkvlvgabv nw nyipam a jokcho yala koksitkokrik singnv gulo gechato Jisu ho lamtv hoka vngpit rilo ninyia kaadubv vla.
Ó sì súré síwájú, ó gun orí igi sikamore kan, kí ó bà lè rí i: nítorí tí yóò kọjá lọ níhà ibẹ̀.
5 Vdwlo Jisu ho hoka vngchi tokudw, nw kaadung toku, okv Jakiasnyi minto, “Baapubv itoku, Jakias, ogulvgavbolo ngo silu noogv naam lo doorung tvvdunv.”
Nígbà tí Jesu sì dé ibẹ̀, ó gbé ojú sókè, ó sì rí i, ó sì wí fún un pé, “Sakeu! Yára, kí o sì sọ̀kalẹ̀; nítorí pé èmi yóò wọ ilé rẹ lónìí.”
6 Jakias baapubv geludanv ngv achialvbv himpula ninyia alvbv aamu toku.
Ó sì yára, ó sọ̀kalẹ̀, ó sì fi ayọ̀ gbà á.
7 Nyi mvnwng hum kaanv vdwv arwnglo mimi sinyato, “So nyi angv si rimurnv nyi gv naam lo nyen bv aadunv!”
Nígbà tí wọ́n sì rí i, gbogbo wọn ń kùn, wí pé, “Ó lọ bá ọkùnrin ẹlẹ́ṣẹ̀ náà ní àlejò.”
8 Jakias dakrap dato okv Jisunyi minto, “Tamsarnv, tvvrialabv! Ngo ngoogv yikungyira nga tunggonyi heemanv vdwa jireku, okv ngo yvvnyi dvkup pvkudw, ngo ninyia api yagu jiya reku.”
Sakeu sì dìde, ó sì wí fún Olúwa pé, “Wò ó, Olúwa, ààbọ̀ ohun ìní mi ni mo fi fún tálákà; bí mo bá sì fi èké gba ohun kan lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, èmi san án padà ní ìlọ́po mẹ́rin!”
9 Jisu ninyia minto, “Silu so gv naam so ringnam v aapvku, ho lvga so nyi si Abraham gvka husi v.
Jesu sì wí fún un pé, “Lónìí ni ìgbàlà wọ ilé yìí, níwọ̀n bí òun pẹ̀lú ti jẹ́ ọmọ Abrahamu.
10 Nyia Kuunyilo ngv nyekunv vdwa makarla ringdukubv aapvnv.”
Nítorí Ọmọ Ènìyàn dé láti wá àwọn tí ó nù kiri, àti láti gbà wọ́n là.”
11 Nyi vdwgv um tvria rilo, Jisu mimbwngla minchisinam go bunua mintamto. Nw vjak Jerusalem lo aachi dvlvbv ritoku, okv Pwknvyarnv gv Karv ngv aadaribo vla bunu mvngnyato.
Nígbà tí wọ́n sì ń gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, ó sì tẹ̀síwájú láti pa òwe kan, nítorí tí ó súnmọ́ Jerusalẹmu, àti nítorí tí wọn ń rò pé, ìjọba Ọlọ́run yóò farahàn nísinsin yìí.
12 Vkvlvgabv nw minto “Hoka ho nyi ako kaibv mvngdvnam go dooto nw aduko mookulo vngtv nvgo Dvbv bv mvku dvbv vla, ho kochingbv nw naam aakur dubv vla rungto.
Ó sì wí pé, “Ọkùnrin ọlọ́lá kan lọ sí ìlú òkèrè láti gba ìjọba kí ó sì padà.
13 Nw gv vngrap maadvbv, nw ninyigv pakbu vring vdwa gokkumto okv bunua ain lokdwng vkv charchak go jigvrila minto, ‘Kaatoka ngoogv vngro rilo nonu so sam ogugo pwlwkpaalwk la pwtam paatam rila rinv.’
Ó sì pe àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ mẹ́wàá, ó fi owó mina mẹ́wàá fún wọn, ó sì wí fún wọn pé, ‘Ẹ máa ṣòwò títí èmi ó fi dé!’
14 Vjak, ninyigv mookugv nyi vdwv ninyia kaanwng mato, okv vkvlvgabv bunu gindungpingko vdwa mimu dubv vla ninyigv kochinglo vngmuto, ‘Ngonu so nyi sum ngonugv Dvbv bv vla mvngma dunv.’”
“Ṣùgbọ́n àwọn ará ìlù rẹ̀ kórìíra rẹ̀, wọ́n sì rán ikọ̀ tẹ̀lé e, wí pé, ‘Àwa kò fẹ́ kí ọkùnrin yìí jẹ ọba lórí wa.’
15 “Nyi anga Dvbv bv mvtoku okv aakur toku. Nw pakbu vdwa ninyigv kaagialo lvkin gubv aadum dubv minto, bunu vdwgo pwkumpaakum pvdw um kaadubv vla.
“Nígbà tí ó gba ìjọba tan, tí ó padà dé, ó pàṣẹ pé, kí a pe àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ wọ̀nyí tí òun ti fi owó fún wá sọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí kí ó le mọ iye èrè tí olúkúlùkù ti jẹ nínú iṣẹ́ òwò wọn.
16 Atokchogv angv aatoku okv minto, ‘Tamsarnv, ngo ain lokdwng charring go paakumpv noogv charkin go jiku lokv.’
“Èyí èkínní sì wá, ó wí pé, ‘Olúwa, owó mina rẹ jèrè owó mina mẹ́wàá sí i.’
17 ‘Alvbv ripv,’ nw mintoku: ‘No alvnv pakbu go! no miangnv yikungyira lo jwkjwkvrwkbv rinv go, ngo nam pamtv vring nga rigvdubv jidunv.’
“Olúwa rẹ̀ sì wí fún un pé, ‘O ṣeun, ìwọ ọmọ ọ̀dọ̀ rere! Nítorí tí ìwọ ṣe olóòtítọ́ ní ohun kínkínní, gba àṣẹ lórí ìlú mẹ́wàá.’
18 Anyi nvnv pakbu angv aato okv minto, ‘Tamsarnv, ngo ain lokdwng charngu go paakumpv no gv charkin go jiku lokv.’
“Èyí èkejì sì wá, ó wí pé, ‘Olúwa, owó mina rẹ jèrè owó mina márùn.’
19 So anga nw minto, ‘No pamtv angu a rigvnvbv rire.’
“Olúwa rẹ sì wí fún un pẹ̀lú pé, ‘Ìwọ pẹ̀lú joyè ìlú márùn-ún!’
20 Pakbu gunv aato okv minto, ‘Tamsarnv, siinv noogv ain lokdwng ngv; ngo sam jeriap gulo vvsi pvnv.
“Òmíràn sì wá, ó wí pé, ‘Olúwa, wò ó owó mina rẹ tí ń bẹ lọ́wọ́ mi ni mo dì sínú aṣọ pélébé kan;
21 Ngo nam busuto, ogulvgavbolo no nyi kingin nvgo. No nokv gvnga maka naadu okv noogv paklwk maanam humka nvvdu.’
nítorí mo bẹ̀rù rẹ, àti nítorí tí ìwọ ṣe òǹrorò ènìyàn, ìwọ a máa mú èyí tí ìwọ kò fi lélẹ̀, ìwọ a sì máa ká èyí tí ìwọ kò gbìn!’
22 Nw pakbu anga minto, ‘No alvmanv pakbu! ngo noogv mvnggwngbv alvmanv gaam um minnvla nam miakayare! No nga gwlwknv nyi go, ngo gvngv manv ngaaka naanv gubv okv ngoogv paklwk maanam humka nvvnv gubv chimpvi.
“Olúwa rẹ sì wí fún un pé, ‘Ní ẹnu ara rẹ náà ni èmi ó ṣe ìdájọ́ rẹ, ìwọ ọmọ ọ̀dọ̀ búburú, ìwọ mọ̀ pé òǹrorò ènìyàn ni mí, pé, èmi a máa mú èyí tí èmi kò fi lélẹ̀ èmi a sì máa ká èyí tí èmi kò gbìn.
23 Alvdu, vbvrikunamv, no ogubv ngoogv morko nga Benk morko kuu bvngkulo lwkma pvnv? Vbvrikunamv ngo naakur rikunyi morko kuu a lvkobv naaku svnga.’
Èéha sì ti ṣe tí ìwọ kò fi owó mi pamọ́ sí ilé ìfowópamọ́, pé nígbà tí mo bá dé, èmi ìbá ti béèrè rẹ̀ pẹ̀lú èlé?’
24 Vbvrikunamv nw hoka daknv vdwa minto, ‘Nw gvlokv ain lokdwng nga naatokuka okv hum Pakbu ain lokdwng charring go doonv yanga jitoka.’
“Ó sì wí fún àwọn tí ó dúró létí ibẹ̀ pé, ‘Ẹ gba owó mina náà lọ́wọ́ rẹ̀, kí ẹ sì fi í fún ẹni tí ó ní owó mina mẹ́wàá.’
25 Vbvritola bunu ninyia minto, ‘Tamsarnv, nw lokdwng charring go doogvla doopv!’
“Wọ́n sì wí fún un pé, ‘Olúwa, ó ní owó mina mẹ́wàá.’
26 ‘Ngo nonua mindunv,’ nw mirwkto, ‘Nyidum mvnwngnga yvvdw ogugo doodunv, hum jidv yayare; vbvritola yvvdw ogugoka kaama dunv, ninyigv achukgo doogv namaka um ninyigv lokv naaritre.
“Mo wí fún yín pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó ní, ni a ó fi fún, àti lọ́dọ̀ ẹni tí kò ní èyí tí ó ní pàápàá a ó gbà á lọ́wọ́ rẹ̀.
27 Vjak, ngoogv nyiru minsunv vdwa yvvbunudw nga bunugv Dvbv bv mvnwng madunv vdwa, bunua so naalwk tvka okv ngoogv dooku soka mvki tokuka!’”
Ṣùgbọ́n àwọn ọ̀tá mi wọ̀nyí, tí kò fẹ́ kí èmi jẹ ọba lórí wọn ẹ mú wọn wá ìhín yìí, kí ẹ sì pa wọ́n níwájú mi!’”
28 Jisu hum mintoku okv vbvrikunamv bunua vngchoyala Jerusalem bv vngto.
Nígbà tí ó sì ti wí nǹkan wọ̀nyí tan, ó lọ síwájú, ó ń gòkè lọ sí Jerusalẹmu.
29 Nw Betpej okv Betani gv adar Olib moodw lo aarilo, nw lvbwlaksu anyigo vngcho moto
Ó sì ṣe, nígbà tí ó súnmọ́ Betfage àti Betani ní òkè tí a ń pè ní òkè olifi, ó rán àwọn méjì nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
30 svbv mingvrila: “Vngnyika nonugv vnglwkjiku nampum alo; nonugv vnglwk rilo, nonu siak ako riokwka manamgo takpvla vvpvnamgo kaapare. Um paksoklaila soka aagv tvika.
Wí pé, “Ẹ lọ sí ìletò tí ó kọjú sí yín; nígbà tí ẹ̀yin bá wọ̀ ọ́ lọ, ẹ̀yin ó rí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan tí a so, tí ẹnikẹ́ni kò gùn rí, ẹ tú u, kí ẹ sì fà á wá.
31 Nyi gonv nonua hum ogubv paksok dunv vla minbo loka, Ahtu sum dinchidukv vla ninyia minpa laka.”
Bí ẹnikẹ́ni bá sì bi yín pé, ‘Èéṣe tí ẹ̀yin fi ń tú u?’ Kí ẹ̀yin wí báyìí pé, ‘Olúwa ń fẹ́ lò ó.’”
32 Bunu bunugv lamtvlo vngkunamv Jisu gv bunua minam jvbv ogumvnwng nga paatoku.
Àwọn tí a rán sì mú ọ̀nà wọn pọ̀n, wọ́n sì bá a gẹ́gẹ́ bí ó ti wí fún wọn.
33 Bunugv siak a paksok rilo, ho gv atu v bunua minto, “nonuno um ogubv paksok dunvla?”
Bí wọ́n sì ti ń tú ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà, àwọn Olúwa rẹ̀ bi wọ́n pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin fi ń tu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà?”
34 “Ahtu sum dinchidu,” bunu mirwkto,
Wọ́n sì wí pé, “Olúwa fẹ́ lò ó.”
35 okv bunu siak a naalaila Jisu gvlo aagv jitoku. Vbvrikunamv bunu bunugv vji a siak aolo puchato okv Jisunyi siak aolo chadubv ridurto.
Wọ́n sì fà á tọ Jesu wá, wọ́n sì tẹ́ aṣọ sí ẹ̀yìn ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà, wọ́n sì gbé Jesu kà á.
36 Ninyigv siak aolo vngrilo nyi vdwv lamtvlo bunugv vji vdwa pipv nyato.
Bí ó sì ti ń lọ wọ́n tẹ́ aṣọ wọn sí ọ̀nà.
37 Vdwlo Nw Jerusalem gv nvchilo aatokudw, Olib moodw bv lamtv ilwk jiku mooku hoka, ninyigv lvbwlaksu vdwv twngtv rungbv bunugv ninyigvlo kaanam mvnwngnga Pwknvyarnvnyi umbonyikv vla okv ninyia hartvla minrap nyatoku:
Bí ó sì ti súnmọ́ etí ibẹ̀ ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè olifi, gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn bẹ̀rẹ̀ sí í yọ̀, wọ́n sì fi ohùn rara yin Ọlọ́run, nítorí iṣẹ́ ńlá gbogbo tí wọ́n ti rí,
38 “Pwknvyarnv ayalaka Dvbvnyi yvvdw Ahtu gv amin lokv aanvnga! Nyidomooku lo sarsopoyo reku okv Pwknvyarnv gvlo kairungbv!”
wí pé, “Olùbùkún ni ọba tí ó ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa!” “Àlàáfíà ní ọ̀run, àti ògo ni òkè ọ̀run!”
39 Vbvrikunamv nyipam lokv Parisis megonv Jisunyi minto. “Tamsarnv,” bunu minto “Noogv lvbwlaksu vdwa choibvkv vla minto!”
Àwọn kan nínú àwọn Farisi nínú àwùjọ náà sì wí fún un pé, “Olùkọ́ bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ wí.”
40 Jisu mirwkto, “Ngo nonua mindunv bunu choi kubolo, vlwng vdwv bunu atuv gamtv rungbv rumrapre.”
Ó sì dá wọn lóhùn, ó wí fún wọn pé, “Mo wí fún yín, bí àwọn wọ̀nyí bá pa ẹnu wọn mọ́, àwọn òkúta yóò kígbe sókè.”
41 Nw pamtv lo aanwk lvlvto, okv vdwlo nw hum kaapa tokudw, nw ho gv lvgabv kapto,
Nígbà tí ó sì súnmọ́ etílé, ó síjú wo ìlú náà, ó sọkún sí i lórí,
42 minto, “Nonu silu sarsopoyo gv lvgalo ogugo aadu nvdw um chinv guloka! Vbvritola nonu vjak um kaapa kumare!
Ó ń wí pé, “Ìbá ṣe pé ìwọ mọ̀, lónìí yìí, àní ìwọ, ohun tí í ṣe tí àlàáfíà rẹ! Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n pamọ́ kúrò lójú rẹ.
43 Nonua nonugv nyimak vdwv aagvrila goyumgochila vnglin chaalin momabv tumla vvpv dw alu v aariku.
Nítorí ọjọ́ ń bọ̀ fún ọ, tí àwọn ọ̀tá rẹ yóò mọ odi bèbè yí ọ ká, àní tí wọn yóò sì yí ọ ká, wọn ó sì ká ọ mọ́ níhà gbogbo.
44 Bunu nonua achuk goka dooku madubv mvyak mvchakre okv nonugv vlwngsvlu arwnglo doonv nyi vdwaka; vlwng pwgoka dookulo doomu mare, ogulvgavbolo nonu Pwknvyarnv gv vdwlo nonua ringdubv vla aanama kaachin manam lvkwnglo!”
Wọn ó sì wó ọ palẹ̀ ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ pẹ̀lú rẹ; wọn kì yóò sì fi òkúta kan sílẹ̀ lórí ara wọn; nítorí ìwọ kò mọ ọjọ́ ìbẹ̀wò rẹ.”
45 Vbvrikunamv Jisu Pwknvyarnvnaam lo vngtoku okv korvpachu pioknv vdwa charlin raptoku,
Ó sì wọ inú tẹmpili lọ, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí lé àwọn tí ń tà nínú rẹ̀ sóde;
46 bunua minto, “So si Darwknv Kitaplo lvkdu, ‘Ngoogv Naam a kumgingku naam bv vla mindunv.’ Vbvritola nonu hum chonvmvvnv tosiku bv mvpv!”
Ó sì wí fún wọn pé, “A ti kọ̀wé rẹ̀ pé, ‘Ilé mi yóò jẹ́ ilé àdúrà?’ Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti sọ ọ́ di ihò àwọn ọlọ́ṣà.”
47 Jisu alu gv dwkia Pwknvyarnvnaam arwnglo tamsarto. Nyibu butvnv vdwv, Pvbv tamsarnv vdwv, okv nyi vdwa rigvnv vdwv Jisunyi mvki dubv mvngtoku,
Ó sì ń kọ́ni lójoojúmọ́ ní tẹmpili, ṣùgbọ́n àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn akọ̀wé, àti àwọn olórí àwọn ènìyàn ń wá ọ̀nà láti pa á.
48 vbvritola bunu ninyia vbvridubv lamtv paanyu matoku, ogulvgavbolo nyi mvnwngngv ninyia tvvria bwngto, gamgoka nyemu nwngma vla mvngnyato.
Wọn kò sì rí nǹkan kan tí wọn ìbá ṣe; nítorí gbogbo ènìyàn ṣù mọ́ ọn láti gbọ́rọ̀ rẹ̀.

< Luk 19 >