< Jeremia 21 >

1 Detta är det ord som kom till Jeremia från HERREN, när konung Sidkia sände till honom Pashur, Malkias son, och prästen Sefanja, Maasejas son, och lät säga:
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá nígbà tí ọba Sedekiah rán Paṣuri ọmọ Malkiah àti àlùfáà Sefaniah ọmọ Maaseiah sí i; wọ́n wí pé:
2 "Fråga HERREN för oss, då nu Nebukadressar, konungen i Babel, har angripit oss; kanhända vill HERREN handla med oss i enlighet med alla sina förra under, så att denne lämnar oss i fred.
“Wádìí lọ́wọ́ Olúwa fún wa nítorí Nebukadnessari ọba Babeli ń kọlù wá. Bóyá Olúwa yóò ṣe ìyanu fún wa gẹ́gẹ́ bí ti àtẹ̀yìnwá, kí ó sì yípadà kúrò lọ́dọ̀ wa.”
3 Jeremia svarade dem: Så skolen I säga till Sidkia:
Ṣùgbọ́n Jeremiah dáhùn wí pé, “Sọ fún Sedekiah,
4 Så säger HERREN, Israels Gud Se, de vapen i eder hand, med vilka I utanför muren striden mot konungen i Babel och kaldéerna, som belägra eder, dem skall jag vända om och skall famla dem inne i denna stad.
‘Èyí ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli wí, Èmi fẹ́ kọjú idà tí ó wà lọ́wọ́ yín sí yín, èyí tí ẹ̀ ń lò láti bá ọba àti àwọn ará Babeli tí wọ́n wà lẹ́yìn odi jà, Èmi yóò sì kó wọn jọ sínú ìlú yìí.
5 Och jag skall själv strida mot eder med uträckt hand och stark arm, vrede och harm och stor förtörnelse.
Èmi gan an yóò sì bá yín jà pẹ̀lú ohun ìjà olóró nínú ìbínú àti ìrunú líle.
6 Och jag skall slå dem som bo i denna stad, både människor och djur; i svår pest skola de dö.
Èmi yóò sì lu gbogbo ìlú yìí, ènìyàn àti ẹranko, gbogbo wọn ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò kọlù tí wọn yóò sì kú.
7 Och därefter, säger HERREN, skall jag låta Sidkia, Juda konung, och hans tjänare och folket, dem som i denna stad äro kvar efter pesten svärdet och hungersnöden, falla i Nebukadressars, den babyloniske konungens, hand och i deras fienders hand, i de mäns hand, som stå efter deras liv. Och han skall slå dem med svärdsegg; han skall icke skona dem och icke hava någon misskund eller något förbarmande.
Olúwa sọ pé lẹ́yìn èyí, èmi yóò fi Sedekiah ọba Juda, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àti àwọn ènìyàn, àti àwọn tí ó kù ní ìlú yìí lọ́wọ́ àjàkálẹ̀-ààrùn àti lọ́wọ́ idà, àti lọ́wọ́ ìyàn; èmi yóò fi wọ́n lé Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́, àti lé ọwọ́ àwọn ọ̀tá wọn, àti lé ọwọ́ àwọn tí ń lépa ẹ̀mí wọn, òun yóò sì fi ojú idà pa wọ́n, kì yóò sì dá wọn sí, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ní ìyọ́nú tàbí ṣàánú wọn.’
8 Och till detta folk skall du säga Så säger HERREN: Se, jag förelägger eder vägen till livet och vägen till döden.
“Síwájú sí i, sọ fún àwọn ènìyàn, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ: Wò ó, Èmi ń fi ọ̀nà ìyè àti ikú hàn yín.
9 Den som stannar kvar i denna stad, han skall dö genom svärd eller hunger eller pest, men den som går ut och giver sig åt kaldéerna, som belägra eder, han skall få leva och vinna sitt liv såsom ett byte.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá dúró sí ìlú yìí yóò ti ipa idà, ìyàn tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn kú. Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá jáde tí ó sì jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún àwọn Babeli tí ó ń lépa yín yóò sì yè. Òun yóò sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀.
10 Ty jag har vänt mitt ansikte mot denna stad, till dess olycka och icke till dess lycka, säger HERREN. Den skall bliva given i den babyloniske konungens hand, och han skall bränna upp den i eld.
Mo ti pinnu láti jẹ ìlú yìí ní yà, ni Olúwa wí. A ó sì gbé e fún ọba Babeli, yóò sì run ún pẹ̀lú iná.’
11 Och till Juda konungs hus skall du säga: Hören HERRENS ord:
“Ẹ̀wẹ̀, wí fún ìdílé ọba Juda pé, ‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
12 I av Davids hus, så säger HERREN: "Fällen var morgon rätt dom, och rädden den plundrade ur förtryckarens hand, för att icke min vrede må bryta fram såsom en eld och brinna så, att ingen kan utsläcka den" -- detta för deras onda väsendes skull.
Ilé Dafidi èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ: “‘Ṣe ìdájọ́ tí ó tọ́ ní àràárọ̀; yọ ọ́ kúrò lọ́wọ́ ẹni tí ó ń ni í lára ẹni tí a ti jà lólè bí bẹ́ẹ̀ kọ́ ìbínú mi yóò jáde síta, yóò sì jó bí iná. Nítorí ibi tí a ti ṣe yóò sì jó láìsí ẹni tí yóò pa á.
13 Se, jag skall vända mig mot dig, du som bor i dalen, du bergfäste på slätten, säger HERREN, ja, mot eder som sägen: "Vem kan falla över oss, och vem kan tränga in i våra boningar?"
Mo kẹ̀yìn sí ọ, Jerusalẹmu, ìwọ tí o gbé lórí àfonífojì lórí òkúta tí ó tẹ́jú, ni Olúwa wí. Ìwọ tí o ti wí pé, “Ta ni ó le dojúkọ wá? Ta ni yóò wọ inú ibùgbé wa?”
14 Jag skall hemsöka eder efter edra gärningars frukt, säger HERREN. Ja, jag skall tända upp en eld i deras skog, och den skall förtära allt där runt omkring.
Èmi yóò jẹ ọ ní ìyà gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ ni Olúwa wí. Èmi yóò mú kí iná jó ilé rẹ̀; yóò si jó gbogbo ohun tí ó wà ní àyíká rẹ.’”

< Jeremia 21 >