< Jeremia 24 >
1 HERREN lät mig se följande syn: Jag fick se två korgar med fikon uppställda framför HERRENS tempel; och det var efter det att Nebukadressar, konungen i Babel, hade fört bort ifrån Jerusalem Jekonja, Jojakims son, konungen i Juda, så ock Juda furstar, jämt timmermännen och smederna, och låtit dem komma till Babel.
Lẹ́yìn tí Nebukadnessari ọba Babeli ti kó Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn oníṣọ̀nà àti oníṣẹ́ ọwọ́ ti Juda lọ sí ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí ilẹ̀ àjèjì Babeli tán. Olúwa fi agbọ̀n èso ọ̀pọ̀tọ́ méjì hàn mí tí a gbé sí iwájú pẹpẹ Olúwa.
2 I den ena korgen funnos mycket goda fikon, sådana som fikon ifrån förstlingsskörden äro; och i de andra korgen funnos mycket usla fikon, så usla att de icke kunde ätas.
Agbọ̀n kan ni èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó dára bí èyí tí ó tètè pọ́n; èkejì sì ní èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó burú rékọjá tí kò sì le è ṣe é jẹ.
3 Och HERREN sade till mig: »Vad ser du, Jeremia?» Jag svarade »Fikon; och de goda fikonen är mycket goda, men de usla fikonen äro mycket usla, så usla att de icke kunna ätas.»
Nígbà náà ni Olúwa bi mí pé, “Kí ni ìwọ rí Jeremiah?” Mo dáhùn pe, “Èso ọ̀pọ̀tọ́.” Mo dáhùn. “Èyí tí ó dáradára púpọ̀, ṣùgbọ́n èyí tí ó burú burú rékọjá tí kò sì ṣe é jẹ.”
4 Och HERRENS ord kom till mig han sade:
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
5 Så säger HERREN, Israels Gud: Såsom man med välbehag ser på de goda fikonen, så vill jag med välbehag se till de bortförda av Juda, dem som jag från denna plats har sänt bort till kaldéernas land.
“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Gẹ́gẹ́ bí àwọn èso ọ̀pọ̀tọ́ dáradára yìí ni Èmi yóò ka àwọn tí wọ́n lọ sí ilẹ̀ àjèjì láti Juda sí tí èmi rán jáde kúrò ní ibí yìí lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kaldea.
6 Jag skall med välbehag vända mitt öga till dem och låta dem komma tillbaka till detta land. Jag skall uppbygga dem och icke slå ned dem; jag skall plantera dem och icke upprycka dem.
Ojú mi yóò máa ṣọ́ wọn lọ fún rere, Èmi yóò gbé wọn ró, n kò ní já wọn lulẹ̀. Èmi yóò gbìn wọ́n, n kò sì ní fà wọ́n tu.
7 Och jag skall giva dem hjärtan till att känna att jag är HERREN; och de skola vara mitt folk, och jag skall vara deras Gud. Ty de skola omvända sig till mig av allt sitt hjärta.
Èmi yóò fún wọn ní ọkàn láti mọ̀ mí pé, “Èmi ni Olúwa.” Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi; Èmi ni yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn; nítorí pé wọn yóò padà sọ́dọ̀ mi pẹ̀lú gbogbo ọkàn wọn.
8 Men såsom man gör med usla fikon, som äro så usla att de icke kunna ätas, likaså, säger HERREN, skall jag göra med Sidkia, Juda konung, och med hans furstar och med kvarlevan i Jerusalem, ja, både med dem som hava blivit kvar här i landet och med dem som hava bosatt sig i Egyptens land.
“‘Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí èso ọ̀pọ̀tọ́ tí kò dára, tí ó burú tí kò ṣe é jẹ,’ ni Olúwa wí, ‘bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe pẹ̀lú Sedekiah ọba Juda, àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn tí ó yẹ ní Jerusalẹmu, yálà wọ́n wà lórí ilẹ̀ yìí tàbí wọ́n ń gbé Ejibiti.
9 På alla orter dit jag fördriver dem skall jag göra dem till en varnagel och en skräckbild för alla riken jorden, till en smälek, till ett ordspråk och en visa, och till ett exempel som man nämner, när man förbannar.
Èmi yóò sọ wọ́n di ìwọ̀sí àti ẹni ibi nínú gbogbo ìjọba ayé, láti di ẹni ìfibú àti ẹni òwe, ẹni ẹ̀sín, àti ẹni ẹ̀gàn ní ibi gbogbo tí Èmi ó lé wọn sí.
10 Och jag skall sända bland dem svärd, hungersnöd och pest, till dess att de bliva utrotade ur det land som jag har givit åt dem och deras fäder.
Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn sí wọn, títí tí gbogbo wọn yóò parun lórí ilẹ̀ tí a fún wọn àti fún àwọn baba wọn.’”