< Salmos 87 >

1 Esta casa está descansando en la montaña sagrada.
Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
2 El Señor tiene más amor por las puertas de Sión que por todas las tiendas de Jacob.
Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
3 Nobles cosas se dicen de ti, oh pueblo de Dios. (Selah)
Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
4 Rahab y Babilonia serán nombrados entre los que tienen conocimiento de mí; ver, Filistea y Tiro, con Etiopía; este hombre tuvo su nacimiento allí.
“Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
5 Y de Sion se dirá: Este o aquel hombre tuvo su nacimiento allí; y el Altísimo la hará fuerte.
Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
6 El Señor tendrá presente, cuando escriba los registros de las personas, que este hombre nació allí. (Selah)
Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
7 Los que cantan y los que bailan, dirán: Todas mis fuentes están en ti.
Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”

< Salmos 87 >