< 1 Crónicas 8 >

1 Benjamín fue el padre de Bela, su hijo mayor, Ashbel el segundo; y Ahara el tercero;
Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
2 Noha el cuarto; y Rapha el quinto;
Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
3 Y Bela tuvo hijos, Adar, Gera, Abiud,
Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
4 Y Abisua y Naaman y Ahoa.
Abiṣua, Naamani, Ahoa,
5 Y Gera y Sefufan e Hiram.
Gera, Ṣefufani àti Huramu.
6 Y estos son los hijos de Aod, jefes de familia de los que viven en Geba:
Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
7 Y Naamán, Ahías, Gera; fue el padre de Uza y Ahihud.
Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
8 Y Saharaim se convirtió en el padre de los niños en el país de los moabitas, después de divorciar a Husim y Beera de sus esposas;
A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
9 Y por su esposa Hodes, se convirtió en el padre de Jobab, Zibia, Mesa y Malcam.
Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
10 Y Jeuz y Saquias y Mirma. Estos fueron sus hijos, jefes de familia.
Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
11 Y Husim fue el padre de Abitob y Elpaal.
Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
12 Y los hijos de Elpaal: Eber, Misam y Semed él fue el constructor de Ono y Lod y sus aldeas;
Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
13 Y Bería y Sema, que eran jefes de las familias de los que vivían en Ajalón, que hicieron huir a las personas que viven en Gat;
Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
14 Y sus hermanos Sasac y Jeroham.
Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
15 Y Zebadias, Arad, y Ader.
Sebadiah, Aradi, Ederi
16 Y Micael, Ispá, Joha, los hijos de Bería;
Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
17 Y Zebadias y Mesulam, Hizqui, Heber.
Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
18 E Ismerai, Jezlias y Jobab, los hijos de Elpaal;
Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
19 Y Jaquim, Zicri, Zabdi.
Jakimu, Sikri, Sabdi,
20 Y Elienai, Ziletai, Eliel.
Elienai, Siletai, Elieli,
21 Y Adaías, Beraías y Simrat, hijos de Simei;
Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
22 E Islam, Heber y Eliel.
Iṣipani Eberi, Elieli,
23 Y Abdon, Zicri y Hanan.
Abdoni, Sikri, Hanani,
24 Y Hananías, Elam y Anatotias.
Hananiah, Elamu, Anitotijah,
25 Ifdaias y Peniel, los hijos de Sasac;
Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
26 Y Samserai, Seharia, y Atalias.
Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
27 Y Jaresias, Elías y Zicri, los hijos de Jeroham.
Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
28 Estos eran jefes de familia en sus generaciones: estos vivían en jerusalén.
Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
29 Y en Gabaón vivía el padre de Gabaón, Jehiel, cuya esposa se llamaba Maaca;
Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
30 Y su hijo mayor, Abdón, Zur, Cis, Baal, Ner, Nadab.
àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
31 Y Gedor, Ahio, Zequer, y Miclot,
Gedori Ahio, Sekeri
32 Y Miclot fue el padre de Simea. Y vivían con sus hermanos en Jerusalén.
pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
33 Y Ner fue el padre de Cis, y Cis fue el padre de Saúl, y Saúl fue el padre de Jonatán, Malquisua, Abinadab y Es Baal.
Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
34 Y el hijo de Jonatán fue Merib-baal; y Merib-baal fue el padre de Micaia.
Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
35 Y los hijos de Micaia: Pitón, Melec, Tarea y Acaz.
Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
36 Y Acaz fue el padre de Joada; y Joada fue el padre de Alemet, Azmavet y Zimri; y Zimri fue el padre de Mosa;
Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
37 Y Mosa fue el padre de Bina: Rafa fue su hijo, Elasa su hijo, Azel su hijo;
Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
38 Y Azel tuvo seis hijos, cuyos nombres son: Azricam, su hijo mayor, Bocru, Ismael y Searias y Obadiah y Hanan. Todos estos fueron los hijos de Azel.
Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
39 Y los hijos de Esec su hermano: Ulam su hijo mayor, Jehus el segundo; y Elifelet el tercero;
Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
40 Y los hijos de Ulam eran hombres de guerra, expertos en el manejo de arcos, y tenían gran número de hijos y nietos, ciento cincuenta. Todos estos fueron los hijos de Benjamín.
Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.

< 1 Crónicas 8 >