< Salmos 124 >
1 A no haber estado Jehová por nosotros, díga lo ahora Israel:
Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi. “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa,” kí ni Israẹli kí ó máa wí nísinsin yìí;
2 A no haber estado Jehová por nosotros, cuando se levantaron contra nosotros los hombres;
ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa, nígbà tí àwọn ènìyàn gbógun sí wa,
3 Vivos nos tragaran entonces: cuando se encendió su furor en nosotros:
nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè nígbà tí ìbínú wọn ru sí wa,
4 Entonces las aguas inundaran sobre nosotros: el arroyo pasara sobre nuestra alma.
nígbà náà ni omi wọ̀n-ọn-nì ìbá bò wá mọ́lẹ̀,
5 Entonces pasaran sobre nuestra alma las aguas soberbias.
nígbà náà ni agbéraga omi ìbá borí ọkàn wa.
6 Bendito Jehová que no nos dio por presa a sus dientes.
Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n bí ohun ọdẹ fún eyín wọn.
7 Nuestra alma, como ave, escapó del lazo de los cazadores: el lazo se quebró, y nosotros escapamos.
Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ; okùn já àwa sì yọ.
8 Nuestro socorro fue en el nombre de Jehová, que hizo el cielo y la tierra.
Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa, tí ó dá ọ̀run òun ayé.